Add parallel Print Page Options

31 “Nígbà náà, Èmi yóò jẹ́ Ọlọ́run fún gbogbo ìdílé ìran Israẹli, àwọn náà yóò sì jẹ́ ènìyàn mi,” ni Olúwa wí.

Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

“Àwọn ènìyàn tí ó sá àsálà lọ́wọ́ idà
    yóò rí ojúrere Olúwa ní aṣálẹ̀,
    Èmi yóò sì fi ìsinmi fún Israẹli.”

Olúwa ti fi ara rẹ̀ hàn wá ní ìgbà kan rí, ó wí pé:

“Èmi ti nífẹ̀ẹ́ yín pẹ̀lú ìfẹ́ àìlópin;
    mo ti fi ìfẹ́ ńlá fà yín,
Èmi yóò tún gbé e yín sókè,
    àní a ó tún gbé e yín ró ìwọ wúńdíá ilẹ̀ Israẹli.
Àní ẹ ó tún tún ohun èlò orin yín gbé,
    ẹ ó sì jáde síta pẹ̀lú ijó àti ayọ̀.
Ẹ ó tún gbin ọgbà àjàrà
    ní orí òkè Samaria;
àwọn àgbẹ̀ yóò sì máa
    gbádùn èso oko wọn.
Ọjọ́ kan máa wà tí àwọn olùṣọ́ yóò kígbe jáde
    lórí òkè Efraimu wí pé,
‘Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a gòkè lọ sí Sioni,
    ní ọ̀dọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa.’ ”

Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa sọ wí pé:

“Ẹ fi ayọ̀ kọrin sí Jakọbu;
    ẹ hó sí olórí àwọn orílẹ̀-èdè gbogbo.
Jẹ́ kí wọ́n gbọ́ ìyìn rẹ kí o sì wí pé,
    Olúwa, gba àwọn ènìyàn rẹ là;
    àwọn tí ó ṣẹ́kù ní Israẹli.’
Wò ó, Èmi yóò mú wọn wá láti ilẹ̀ àríwá;
    èmi yóò kó gbogbo wọn jọ láti òpin ayé.
Lára wọn ni yóò jẹ́ afọ́jú àti arọ,
    aboyún àti obìnrin tí ń rọbí,
    ọ̀pọ̀ ènìyàn yóò wá.
Wọn yóò wá pẹ̀lú ẹkún,
    wọn yóò gbàdúrà bí Èmi yóò ṣe mú wọn padà.
Èmi yóò jẹ́ atọ́nà fún wọn ní ẹ̀bá odò omi;
    ní ọ̀nà tí ó tẹ́jú tí wọn kì yóò le ṣubú,
nítorí èmi ni baba Israẹli,
    Efraimu sì ni àkọ́bí ọkùnrin mi.

10 “Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ẹ̀yin orílẹ̀-èdè
    ẹ kéde rẹ̀ ní erékùṣù jíjìn;
‘Ẹni tí ó bá tú Israẹli ká yóò kójọ,
    yóò sì ṣọ́ agbo rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí olùṣọ́-àgùntàn.’
11 Nítorí Olúwa ti tú Jakọbu sílẹ̀, o sì rà á padà
    ní ọwọ́ àwọn tí ó lágbára jù ú lọ
12 Wọn yóò wá, wọn ó sì hó ìhó ayọ̀ lórí òkè Sioni;
    wọn yóò yọ ayọ̀ níbi oore Olúwa.
Àlìkámà ni, ọtí wáìnì tuntun àti òróró
    ọ̀dọ́-àgùntàn àti ọ̀dọ́ ọ̀wọ́ ẹran.
Wọn ó dàbí ọgbà àjàrà tí a bomirin,
    ìkorò kò ní bá wọn mọ́.
13 Àwọn wúńdíá yóò jó, wọn ó sì kún fún ayọ̀,
    bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni ọkùnrin àti obìnrin.
Èmi yóò sọ ọ̀fọ̀ wọn di ayọ̀,
    dípò ìkorò èmi yóò tù wọ́n nínú.
    Èmi ó sì fún wọn ní ayọ̀.
14 Èmi ó tẹ́ àwọn àlùfáà lọ́rùn pẹ̀lú ọ̀pọ̀;
    àwọn ènìyàn mi yóò sì kún fún oore mi,”
    ni Olúwa wí.

15 (A)Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

“A gbọ́ ohùn kan ní Rama
    tí ń ṣọ̀fọ̀ pẹ̀lú ẹkún kíkorò.
Rakeli ń sọkún àwọn ọmọ rẹ̀;
    kò gbà kí wọ́n tu òun nínú,
    nítorí àwọn ọmọ rẹ̀ kò sí mọ́.”

16 Báyìí ni Olúwa wí:

“Dá ohùn rẹ dúró nínú ẹkún
    àti ojú rẹ nínú omijé;
nítorí a ó fi èrè sí iṣẹ́ rẹ,”
    ni Olúwa wí.
    “Wọn ó sì padà wá láti ilẹ̀ ọ̀tá.
17 Nítorí ìrètí wà fún ọjọ́ iwájú rẹ,”
    ni Olúwa wí.
    “Àwọn ọmọ rẹ yóò padà wá sí ilẹ̀ wọn.

18 “Nítòótọ́, èmi ti gbọ́ ìpohùnréré Efraimu wí pé,
    ‘Ìwọ ti bá mi wí gẹ́gẹ́ bí ọmọ màlúù tí a kò kọ́
èmi sì ti gbọ́ ìbáwí.
    Rà mí padà, èmi yóò sì yípadà,
    nítorí ìwọ ni Olúwa Ọlọ́run mi.
19 Lẹ́yìn tí èmi ti yípadà,
    mo ronúpìwàdà,
lẹ́yìn tí èmi ti wá mọ̀,
    èmi lu àyà mi.
Ojú tì mí, mo sì dààmú;
    nítorí èmi gba èrè ẹ̀gàn ìgbà èwe mi.’
20 Efraimu kì í ha í ṣe ọmọkùnrin mi dáradára
    tí inú mi dùn sí bí?
Bí èmi ti ń sọ̀rọ̀ sí i tó,
    síbẹ̀, èmi rántí rẹ̀.
Nítorí náà, ọkàn mi ṣe ohun kan fún un,
    èmi káàánú gidigidi fún un,”
    ni Olúwa wí.

21 “Gbé ààmì ojú ọ̀nà dìde,
    ṣe atọ́nà ààmì,
kíyèsi òpópó ọ̀nà geere
    ojú ọ̀nà tí ó ń gbà.
Yípadà ìwọ wúńdíá Israẹli,
    padà sí àwọn ìlú rẹ.
22 Ìwọ yóò ti ṣìnà pẹ́ tó,
    ìwọ aláìṣòótọ́ ọmọbìnrin;
Olúwa yóò dá ohun tuntun lórí ilẹ̀,
    ọmọbìnrin kan yóò yí ọkùnrin kan ká.”

23 Báyìí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Israẹli wí: “Nígbà tí èmi bá kó wọn dé láti ìgbèkùn; àwọn ènìyàn tí ó wà ní ilẹ̀ Juda àti ní àwọn ìlú rẹ̀ yóò tún lo àwọn ọ̀rọ̀ yìí lẹ́ẹ̀kan sí i; wí pé, ‘Kí Olúwa kí ó bùkún fún ọ, ìwọ ibùgbé òdodo, ìwọ òkè ìwà mímọ́.’ 24 Àwọn ènìyàn yóò gbé papọ̀ ní Juda àti ní gbogbo àwọn ìlú rẹ̀; bákan náà ni àgbẹ̀ àti àwọn tí ń tẹ̀lé agbo ẹran wọn ká. 25 Èmi yóò sọ aláàárẹ̀ di ọ̀tun, èmi yóò sì tẹ́ gbogbo ọkàn tí ń káàánú lọ́rùn.”

26 Lórí èyí ni mo jí, mo sì wò yíká, oorun mi sì dùn mọ́ mi.

27 “Wò ó, ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “nígbà tí èmi yóò gbin ilé Israẹli àti ilé Juda pẹ̀lú irúgbìn ọmọ ènìyàn àti ẹranko. 28 Gẹ́gẹ́ bí mo ṣe ń ṣọ́ wọn, láti fàtu, àti láti wó lulẹ̀, àti láti gba ìṣàkóso, láti bàjẹ́ àti láti mú ibi wá, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò ṣọ́ wọn láti kọ́ àti láti gbìn,” ni Olúwa wí. 29 “Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àwọn ènìyàn kò ní sọ mọ́ pé:

“ ‘Àwọn baba ti jẹ èso àjàrà àìpọ́n
    àti pé eyín kan àwọn ọmọdé.’

30 Ṣùgbọ́n olúkúlùkù ni yóò kú fún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ èso kíkan ni eyín yóò kan.

31 (B)(C) “Ìgbà kan ń bọ̀,” ni Olúwa wí,
    “tí Èmi yóò bá ilé Israẹli
àti ilé Juda dá májẹ̀mú tuntun.
32 Kò ní dàbí májẹ̀mú
    tí mo bá àwọn baba ńlá wọn dá,
nígbà tí mo fà wọ́n lọ́wọ́,
    tí mo mú wọn jáde ní Ejibiti
nítorí wọ́n da májẹ̀mú mi.
    Lóòótọ́ ọkọ ni èmi jẹ́ fún wọn,”
    ni Olúwa wí.
33 “Èyí ni májẹ̀mú tí èmi yóò bá ilé Israẹli dá
    lẹ́yìn ìgbà náà,” ni Olúwa wí pé:
“Èmi yóò fi òfin mi sí ọkàn wọn,
    èmi ó sì kọ ọ́ sí àyà wọn.
Èmi ó jẹ́ Olúwa wọn;
    àwọn ó sì jẹ́ ènìyàn mi.
34 Kò ní sí pé ọkùnrin kan ń kọ́ àwọn ará ilé rẹ̀
    tàbí ọkùnrin ń kọ́ arákùnrin rẹ̀ pé, ‘Ẹ mọ Olúwa,’
nítorí gbogbo wọn ni yóò mọ̀ mí
    láti ẹni kékeré wọn títí dé ẹni ńlá,”
    ni Olúwa wí.
“Nítorí èmi ó dárí àìṣedéédéé wọn jì,
    èmi kò sì ní rántí ẹ̀ṣẹ̀ wọn mọ́.”

35 Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

ẹni tí ó mú oòrùn
    tan ìmọ́lẹ̀ ní ọ̀sán,
tí ó mú òṣùpá àti ìràwọ̀
    ràn ní òru;
tí ó rú omi Òkun sókè
    tó bẹ́ẹ̀ tí Ìjì rẹ̀ fi ń hó
    Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀.
36 “Àyàfi tí ìlànà yìí bá kúrò níwájú mi,”
    ni Olúwa wí.
“Ǹjẹ́ àwọn ọmọ Israẹli yóò dẹ́kun
    láti jẹ́ orílẹ̀-èdè níwájú mi láéláé.”

37 Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

“Àyàfi tí a bá lé àwọn ọ̀run lókè
    tí ìpìlẹ̀ ayé sì di àwárí ní ìsàlẹ̀,
ni èmi yóò kọ àwọn Israẹli
    nítorí ohun gbogbo tí wọ́n ti ṣe,”
    ni Olúwa wí.

38 “Ọjọ́ náà ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí wọn yóò tún ìlú yìí kọ́ fún mi láti ilé ìṣọ́ Hananeli dé igun ẹnu ibodè. 39 Okùn ìwọ̀n yóò sì nà jáde láti ibi gígùn lọ sí òkè Garebu yóò sì lọ sí Goa. 40 Gbogbo Àfonífojì níbi tí wọ́n ń da òkú àti eérú sí, àti gbogbo Àfonífojì Kidironi ní ìhà ìlà-oòrùn títí dé igun ẹnu ibodè ẹṣin yóò jẹ́ mímọ́ sí Olúwa. A kì yóò fa ìlú náà tu tàbí kí a wó o palẹ̀.”

31 “At that time,” declares the Lord, “I will be the God(A) of all the families of Israel, and they will be my people.”

This is what the Lord says:

“The people who survive the sword
    will find favor(B) in the wilderness;
    I will come to give rest(C) to Israel.”

The Lord appeared to us in the past,[a] saying:

“I have loved(D) you with an everlasting love;
    I have drawn(E) you with unfailing kindness.
I will build you up again,
    and you, Virgin(F) Israel, will be rebuilt.(G)
Again you will take up your timbrels(H)
    and go out to dance(I) with the joyful.(J)
Again you will plant(K) vineyards
    on the hills of Samaria;(L)
the farmers will plant them
    and enjoy their fruit.(M)
There will be a day when watchmen(N) cry out
    on the hills of Ephraim,
‘Come, let us go up to Zion,
    to the Lord our God.’”(O)

This is what the Lord says:

“Sing(P) with joy for Jacob;
    shout for the foremost(Q) of the nations.
Make your praises heard, and say,
    Lord, save(R) your people,
    the remnant(S) of Israel.’
See, I will bring them from the land of the north(T)
    and gather(U) them from the ends of the earth.
Among them will be the blind(V) and the lame,(W)
    expectant mothers and women in labor;
    a great throng will return.
They will come with weeping;(X)
    they will pray as I bring them back.
I will lead(Y) them beside streams of water(Z)
    on a level(AA) path where they will not stumble,
because I am Israel’s father,(AB)
    and Ephraim is my firstborn son.

10 “Hear the word of the Lord, you nations;
    proclaim it in distant coastlands:(AC)
‘He who scattered(AD) Israel will gather(AE) them
    and will watch over his flock like a shepherd.’(AF)
11 For the Lord will deliver Jacob
    and redeem(AG) them from the hand of those stronger(AH) than they.
12 They will come and shout for joy(AI) on the heights(AJ) of Zion;
    they will rejoice in the bounty(AK) of the Lord
the grain, the new wine and the olive oil,(AL)
    the young of the flocks(AM) and herds.
They will be like a well-watered garden,(AN)
    and they will sorrow(AO) no more.
13 Then young women will dance and be glad,
    young men and old as well.
I will turn their mourning(AP) into gladness;
    I will give them comfort(AQ) and joy(AR) instead of sorrow.
14 I will satisfy(AS) the priests(AT) with abundance,
    and my people will be filled with my bounty,(AU)
declares the Lord.

15 This is what the Lord says:

“A voice is heard in Ramah,(AV)
    mourning and great weeping,
Rachel weeping for her children
    and refusing to be comforted,(AW)
    because they are no more.”(AX)

16 This is what the Lord says:

“Restrain your voice from weeping
    and your eyes from tears,(AY)
for your work will be rewarded,(AZ)
declares the Lord.
    “They will return(BA) from the land of the enemy.
17 So there is hope(BB) for your descendants,”
declares the Lord.
    “Your children(BC) will return to their own land.

18 “I have surely heard Ephraim’s moaning:
    ‘You disciplined(BD) me like an unruly calf,(BE)
    and I have been disciplined.
Restore(BF) me, and I will return,
    because you are the Lord my God.
19 After I strayed,(BG)
    I repented;
after I came to understand,
    I beat(BH) my breast.
I was ashamed(BI) and humiliated
    because I bore the disgrace of my youth.’(BJ)
20 Is not Ephraim my dear son,
    the child(BK) in whom I delight?
Though I often speak against him,
    I still remember(BL) him.
Therefore my heart yearns for him;
    I have great compassion(BM) for him,”
declares the Lord.

21 “Set up road signs;
    put up guideposts.(BN)
Take note of the highway,(BO)
    the road that you take.
Return,(BP) Virgin(BQ) Israel,
    return to your towns.
22 How long will you wander,(BR)
    unfaithful(BS) Daughter Israel?
The Lord will create a new thing(BT) on earth—
    the woman will return to[b](BU) the man.”

23 This is what the Lord Almighty, the God of Israel, says: “When I bring them back from captivity,[c](BV) the people in the land of Judah and in its towns will once again use these words: ‘The Lord bless(BW) you, you prosperous city,(BX) you sacred mountain.’(BY) 24 People will live(BZ) together in Judah and all its towns—farmers and those who move about with their flocks.(CA) 25 I will refresh the weary(CB) and satisfy the faint.”(CC)

26 At this I awoke(CD) and looked around. My sleep had been pleasant to me.

27 “The days are coming,”(CE) declares the Lord, “when I will plant(CF) the kingdoms of Israel and Judah with the offspring of people and of animals. 28 Just as I watched(CG) over them to uproot(CH) and tear down, and to overthrow, destroy and bring disaster,(CI) so I will watch over them to build and to plant,”(CJ) declares the Lord. 29 “In those days people will no longer say,

‘The parents(CK) have eaten sour grapes,
    and the children’s teeth are set on edge.’(CL)

30 Instead, everyone will die for their own sin;(CM) whoever eats sour grapes—their own teeth will be set on edge.

31 “The days are coming,” declares the Lord,
    “when I will make a new covenant(CN)
with the people of Israel
    and with the people of Judah.
32 It will not be like the covenant(CO)
    I made with their ancestors(CP)
when I took them by the hand
    to lead them out of Egypt,(CQ)
because they broke my covenant,
    though I was a husband(CR) to[d] them,[e]
declares the Lord.
33 “This is the covenant I will make with the people of Israel
    after that time,” declares the Lord.
“I will put my law in their minds(CS)
    and write it on their hearts.(CT)
I will be their God,
    and they will be my people.(CU)
34 No longer will they teach(CV) their neighbor,
    or say to one another, ‘Know the Lord,’
because they will all know(CW) me,
    from the least of them to the greatest,”
declares the Lord.
“For I will forgive(CX) their wickedness
    and will remember their sins(CY) no more.”

35 This is what the Lord says,

he who appoints(CZ) the sun
    to shine by day,
who decrees the moon and stars
    to shine by night,(DA)
who stirs up the sea(DB)
    so that its waves roar(DC)
    the Lord Almighty is his name:(DD)
36 “Only if these decrees(DE) vanish from my sight,”
    declares the Lord,
“will Israel(DF) ever cease
    being a nation before me.”

37 This is what the Lord says:

“Only if the heavens above can be measured(DG)
    and the foundations of the earth below be searched out
will I reject(DH) all the descendants of Israel
    because of all they have done,”
declares the Lord.

38 “The days are coming,” declares the Lord, “when this city will be rebuilt(DI) for me from the Tower of Hananel(DJ) to the Corner Gate.(DK) 39 The measuring line(DL) will stretch from there straight to the hill of Gareb and then turn to Goah. 40 The whole valley(DM) where dead bodies(DN) and ashes are thrown, and all the terraces out to the Kidron Valley(DO) on the east as far as the corner of the Horse Gate,(DP) will be holy(DQ) to the Lord. The city will never again be uprooted or demolished.”

Footnotes

  1. Jeremiah 31:3 Or Lord has appeared to us from afar
  2. Jeremiah 31:22 Or will protect
  3. Jeremiah 31:23 Or I restore their fortunes
  4. Jeremiah 31:32 Hebrew; Septuagint and Syriac / and I turned away from
  5. Jeremiah 31:32 Or was their master

31 At the same time, saith the Lord, will I be the God of all the families of Israel, and they shall be my people.

Thus saith the Lord, The people which were left of the sword found grace in the wilderness; even Israel, when I went to cause him to rest.

The Lord hath appeared of old unto me, saying, Yea, I have loved thee with an everlasting love: therefore with lovingkindness have I drawn thee.

Again I will build thee, and thou shalt be built, O virgin of Israel: thou shalt again be adorned with thy tabrets, and shalt go forth in the dances of them that make merry.

Thou shalt yet plant vines upon the mountains of Samaria: the planters shall plant, and shall eat them as common things.

For there shall be a day, that the watchmen upon the mount Ephraim shall cry, Arise ye, and let us go up to Zion unto the Lord our God.

For thus saith the Lord; Sing with gladness for Jacob, and shout among the chief of the nations: publish ye, praise ye, and say, O Lord, save thy people, the remnant of Israel.

Behold, I will bring them from the north country, and gather them from the coasts of the earth, and with them the blind and the lame, the woman with child and her that travaileth with child together: a great company shall return thither.

They shall come with weeping, and with supplications will I lead them: I will cause them to walk by the rivers of waters in a straight way, wherein they shall not stumble: for I am a father to Israel, and Ephraim is my firstborn.

10 Hear the word of the Lord, O ye nations, and declare it in the isles afar off, and say, He that scattered Israel will gather him, and keep him, as a shepherd doth his flock.

11 For the Lord hath redeemed Jacob, and ransomed him from the hand of him that was stronger than he.

12 Therefore they shall come and sing in the height of Zion, and shall flow together to the goodness of the Lord, for wheat, and for wine, and for oil, and for the young of the flock and of the herd: and their soul shall be as a watered garden; and they shall not sorrow any more at all.

13 Then shall the virgin rejoice in the dance, both young men and old together: for I will turn their mourning into joy, and will comfort them, and make them rejoice from their sorrow.

14 And I will satiate the soul of the priests with fatness, and my people shall be satisfied with my goodness, saith the Lord.

15 Thus saith the Lord; A voice was heard in Ramah, lamentation, and bitter weeping; Rahel weeping for her children refused to be comforted for her children, because they were not.

16 Thus saith the Lord; Refrain thy voice from weeping, and thine eyes from tears: for thy work shall be rewarded, saith the Lord; and they shall come again from the land of the enemy.

17 And there is hope in thine end, saith the Lord, that thy children shall come again to their own border.

18 I have surely heard Ephraim bemoaning himself thus; Thou hast chastised me, and I was chastised, as a bullock unaccustomed to the yoke: turn thou me, and I shall be turned; for thou art the Lord my God.

19 Surely after that I was turned, I repented; and after that I was instructed, I smote upon my thigh: I was ashamed, yea, even confounded, because I did bear the reproach of my youth.

20 Is Ephraim my dear son? is he a pleasant child? for since I spake against him, I do earnestly remember him still: therefore my bowels are troubled for him; I will surely have mercy upon him, saith the Lord.

21 Set thee up waymarks, make thee high heaps: set thine heart toward the highway, even the way which thou wentest: turn again, O virgin of Israel, turn again to these thy cities.

22 How long wilt thou go about, O thou backsliding daughter? for the Lord hath created a new thing in the earth, A woman shall compass a man.

23 Thus saith the Lord of hosts, the God of Israel; As yet they shall use this speech in the land of Judah and in the cities thereof, when I shall bring again their captivity; The Lord bless thee, O habitation of justice, and mountain of holiness.

24 And there shall dwell in Judah itself, and in all the cities thereof together, husbandmen, and they that go forth with flocks.

25 For I have satiated the weary soul, and I have replenished every sorrowful soul.

26 Upon this I awaked, and beheld; and my sleep was sweet unto me.

27 Behold, the days come, saith the Lord, that I will sow the house of Israel and the house of Judah with the seed of man, and with the seed of beast.

28 And it shall come to pass, that like as I have watched over them, to pluck up, and to break down, and to throw down, and to destroy, and to afflict; so will I watch over them, to build, and to plant, saith the Lord.

29 In those days they shall say no more, The fathers have eaten a sour grape, and the children's teeth are set on edge.

30 But every one shall die for his own iniquity: every man that eateth the sour grape, his teeth shall be set on edge.

31 Behold, the days come, saith the Lord, that I will make a new covenant with the house of Israel, and with the house of Judah:

32 Not according to the covenant that I made with their fathers in the day that I took them by the hand to bring them out of the land of Egypt; which my covenant they brake, although I was an husband unto them, saith the Lord:

33 But this shall be the covenant that I will make with the house of Israel; After those days, saith the Lord, I will put my law in their inward parts, and write it in their hearts; and will be their God, and they shall be my people.

34 And they shall teach no more every man his neighbour, and every man his brother, saying, Know the Lord: for they shall all know me, from the least of them unto the greatest of them, saith the Lord: for I will forgive their iniquity, and I will remember their sin no more.

35 Thus saith the Lord, which giveth the sun for a light by day, and the ordinances of the moon and of the stars for a light by night, which divideth the sea when the waves thereof roar; The Lord of hosts is his name:

36 If those ordinances depart from before me, saith the Lord, then the seed of Israel also shall cease from being a nation before me for ever.

37 Thus saith the Lord; If heaven above can be measured, and the foundations of the earth searched out beneath, I will also cast off all the seed of Israel for all that they have done, saith the Lord.

38 Behold, the days come, saith the Lord, that the city shall be built to the Lord from the tower of Hananeel unto the gate of the corner.

39 And the measuring line shall yet go forth over against it upon the hill Gareb, and shall compass about to Goath.

40 And the whole valley of the dead bodies, and of the ashes, and all the fields unto the brook of Kidron, unto the corner of the horse gate toward the east, shall be holy unto the Lord; it shall not be plucked up, nor thrown down any more for ever.