Add parallel Print Page Options

15 (A)Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

“A gbọ́ ohùn kan ní Rama
    tí ń ṣọ̀fọ̀ pẹ̀lú ẹkún kíkorò.
Rakeli ń sọkún àwọn ọmọ rẹ̀;
    kò gbà kí wọ́n tu òun nínú,
    nítorí àwọn ọmọ rẹ̀ kò sí mọ́.”

Read full chapter

15 This is what the Lord says:

“A voice is heard in Ramah,(A)
    mourning and great weeping,
Rachel weeping for her children
    and refusing to be comforted,(B)
    because they are no more.”(C)

Read full chapter