Add parallel Print Page Options

Olúwa Wa Jọba

14 Kíyèsi i, ọjọ́ Olúwa ń bọ̀, a ó sì pín ìkógun rẹ̀ láàrín rẹ̀.

Nítorí èmi ó kó gbogbo orílẹ̀-èdè jọ sí Jerusalẹmu fún ogun; a ó sì ko ìlú naà, a ó sì kó àwọn ilé, a ó sì ba àwọn obìnrin jẹ́, ààbọ̀ ìlú náà yóò lọ sí ìgbèkùn, a kì yóò sì gé ìyókù àwọn ènìyàn náà kúrò ni ìlú náà. Nígbà náà ni Olúwa yóò jáde lọ, yóò sì bá àwọn orílẹ̀-èdè náà jà, gẹ́gẹ́ bí í ti ìjà ní ọjọ́ ogun. Ẹsẹ̀ rẹ̀ yóò sì dúró ni ọjọ́ náà lórí òkè Olifi, tí ó wà níwájú Jerusalẹmu ni ìlà-oòrùn, òkè Olifi yóò sì là á sí méjì, sí ìhà ìlà-oòrùn àti ìhà ìwọ̀-oòrùn, Àfonífojì ńláńlá yóò wà: ìdajì òkè náà yóò sì ṣí síhà àríwá, àti ìdajì rẹ̀ síhà gúúsù. Ẹ̀yin ó sì sá sí àfonífojì àwọn òkè mi: nítorí pé àfonífojì òkè náà yóò dé Aseli: nítòótọ́, ẹ̀yin ó sá bí ẹ tí sá fún ìmìmì-ilẹ̀ ni ọjọ́ Ussiah ọba Juda: Olúwa Ọlọ́run mi yóò sì wá, àti gbogbo àwọn Ẹni mímọ́ pẹ̀lú rẹ̀.

Yóò sì ṣe ni ọjọ́ náà, ìmọ́lẹ̀ kì yóò mọ́, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò ṣókùnkùn. Ṣùgbọ́n yóò jẹ́ ọjọ́ kan mímọ́ fún Olúwa, kì í ṣe ọ̀sán, kì í ṣe òru; ṣùgbọ́n yóò ṣe pé, ni àṣálẹ́ ìmọ́lẹ̀ yóò wà.

Yóò sì ṣe ní ọjọ́ náà, omi ìyè yóò tí Jerusalẹmu sàn lọ; ìdajì wọn síhà Òkun ìlà-oòrùn, àti ìdajì wọn síhà okùn ẹ̀yìn: nígbà ẹ̀rùn àti nígbà òtútù ni yóò rí bẹ́ẹ̀.

Olúwa yóò sì jẹ ọba lórí gbogbo ayé; ni ọjọ́ náà ni Olúwa kan yóò wa orúkọ rẹ̀ nìkan náà ni orúkọ.

10 A ó yí gbogbo ilẹ̀ padà bi pẹ̀tẹ́lẹ̀ kan láti Geba dé Rimoni lápá gúúsù Jerusalẹmu: yóò di bí aginjù, ṣùgbọ́n a ó sì gbé Jerusalẹmu sókè, yóò sì gbe ipò rẹ̀, láti ibodè Benjamini títí dé ibi ibodè èkínní, dé ibodè igun nì, àti láti ilé ìṣọ́ Hananeli dé ibi ìfúntí wáìnì ọba. 11 (A)Ènìyàn yóò sì máa gbé ibẹ̀, kì yóò sì sí ìparun mọ́; ṣùgbọ́n a ó máa gbé Jerusalẹmu láìléwu.

12 Èyí ni yóò sì jẹ́ ààrùn tí Olúwa yóò fi kọlu gbogbo àwọn ènìyàn ti ó tí ba Jerusalẹmu jà; ẹran-ara wọn yóò rù nígbà tí wọn dúró ni ẹsẹ̀ wọn, ojú wọn yóò sì rà ni ihò wọn, ahọ́n wọn yóò sì bàjẹ́ ni ẹnu wọn. 13 Yóò sì ṣe ni ọjọ́ náà, ìrọ́kẹ̀kẹ̀ ńlá láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá yóò wà láàrín wọn; wọn ó sì di ọwọ́ ara wọn mú, ọwọ́ èkínní yóò sì dìde sì ọwọ́ èkejì rẹ̀. 14 Juda pẹ̀lú yóò sì jà ni Jerusalẹmu: ọrọ̀ gbogbo àwọn kèfèrí tí ó wà káàkiri ni a ó sì kójọ, wúrà àti fàdákà, àti aṣọ, ní ọ̀pọ̀lọpọ̀. 15 Bẹ́ẹ̀ ni ààrùn ẹṣin, ìbáaka, ìbákasẹ, àti tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, yóò sì wà, àti gbogbo ẹranko tí ń bẹ nínú àgọ́.

16 Yóò sì ṣe, olúkúlùkù ẹni tí o kù nínú gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ó dìde sí Jerusalẹmu yóò máa gòkè lọ lọ́dọọdún láti sìn ọba, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, àti láti ṣe àjọyọ̀ àsè àgọ́ náà. 17 Yóò sì ṣe, ẹnikẹ́ni tí kì yóò gòkè wá nínú gbogbo ìdílé ayé sí Jerusalẹmu láti sín ọba, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, òjò kì yóò rọ̀ fún wọn. 18 (B)Bí ìdílé Ejibiti kò bá sì gòkè lọ, tí wọn kò sì wá, fi ara wọn hàn tí wọn kò ní òjò; ààrùn náà yóò wà, tí Olúwa yóò fi kọlù àwọn kèfèrí tí kò gòkè wá láti ṣe àjọyọ̀ àsè àgọ́ náà 19 Èyí ni yóò sì jẹ́ ìyà Ejibiti, àti ìyà gbogbo orílẹ̀-èdè tí kò gòkè wá láti pa àsè àgọ́ mọ́.

20 Ní ọjọ́ náà ni “mímọ́ sí Olúwa” yóò wà lára ṣaworo ẹṣin: àti àwọn ìkòkò ni ilé Olúwa yóò sì dàbí àwọn ọpọ́n tí ń bẹ níwájú pẹpẹ. 21 Nítòótọ́, gbogbo ìkòkò ni Jerusalẹmu àti ni Juda yóò jẹ́ mímọ́ sí Olúwa àwọn ọmọ-ogun: àti gbogbo àwọn tí ń rú ẹbọ yóò wá, wọn ó sì mú ìkòkò díẹ̀, wọn ó sì bọ ẹran wọn nínú rẹ̀, ni ọjọ́ náà ni àwọn Kenaani kò ní sí mọ́ ni ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun.

The Lord Comes and Reigns

14 A day of the Lord(A) is coming, Jerusalem, when your possessions(B) will be plundered and divided up within your very walls.

I will gather all the nations(C) to Jerusalem to fight against it;(D) the city will be captured, the houses ransacked, and the women raped.(E) Half of the city will go into exile, but the rest of the people will not be taken from the city.(F) Then the Lord will go out and fight(G) against those nations, as he fights on a day of battle.(H) On that day his feet will stand on the Mount of Olives,(I) east of Jerusalem, and the Mount of Olives will be split(J) in two from east to west, forming a great valley, with half of the mountain moving north and half moving south. You will flee by my mountain valley, for it will extend to Azel. You will flee as you fled from the earthquake[a](K) in the days of Uzziah king of Judah. Then the Lord my God will come,(L) and all the holy ones with him.(M)

On that day there will be neither sunlight(N) nor cold, frosty darkness. It will be a unique(O) day—a day known only to the Lord—with no distinction between day and night.(P) When evening comes, there will be light.(Q)

On that day living water(R) will flow(S) out from Jerusalem, half of it east(T) to the Dead Sea and half of it west to the Mediterranean Sea, in summer and in winter.(U)

The Lord will be king(V) over the whole earth.(W) On that day there will be one Lord, and his name the only name.(X)

10 The whole land, from Geba(Y) to Rimmon,(Z) south of Jerusalem, will become like the Arabah. But Jerusalem will be raised up(AA) high from the Benjamin Gate(AB) to the site of the First Gate, to the Corner Gate,(AC) and from the Tower of Hananel(AD) to the royal winepresses, and will remain in its place.(AE) 11 It will be inhabited;(AF) never again will it be destroyed. Jerusalem will be secure.(AG)

12 This is the plague with which the Lord will strike(AH) all the nations that fought against Jerusalem: Their flesh will rot while they are still standing on their feet, their eyes will rot in their sockets, and their tongues will rot in their mouths.(AI) 13 On that day people will be stricken by the Lord with great panic.(AJ) They will seize each other by the hand and attack one another.(AK) 14 Judah(AL) too will fight at Jerusalem. The wealth of all the surrounding nations will be collected(AM)—great quantities of gold and silver and clothing. 15 A similar plague(AN) will strike the horses and mules, the camels and donkeys, and all the animals in those camps.

16 Then the survivors(AO) from all the nations that have attacked Jerusalem will go up year after year to worship(AP) the King,(AQ) the Lord Almighty, and to celebrate the Festival of Tabernacles.(AR) 17 If any of the peoples of the earth do not go up to Jerusalem to worship(AS) the King, the Lord Almighty, they will have no rain.(AT) 18 If the Egyptian people do not go up and take part, they will have no rain. The Lord[b] will bring on them the plague(AU) he inflicts on the nations that do not go up to celebrate the Festival of Tabernacles.(AV) 19 This will be the punishment of Egypt and the punishment of all the nations that do not go up to celebrate the Festival of Tabernacles.(AW)

20 On that day holy to the Lord(AX) will be inscribed on the bells of the horses, and the cooking pots(AY) in the Lord’s house will be like the sacred bowls(AZ) in front of the altar. 21 Every pot in Jerusalem and Judah will be holy(BA) to the Lord Almighty, and all who come to sacrifice will take some of the pots and cook in them. And on that day(BB) there will no longer be a Canaanite[c](BC) in the house(BD) of the Lord Almighty.(BE)

Footnotes

  1. Zechariah 14:5 Or My mountain valley will be blocked and will extend to Azel. It will be blocked as it was blocked because of the earthquake
  2. Zechariah 14:18 Or part, then the Lord
  3. Zechariah 14:21 Or merchant

14 Behold, the day of the Lord cometh, and thy spoil shall be divided in the midst of thee.

For I will gather all nations against Jerusalem to battle; and the city shall be taken, and the houses rifled, and the women ravished; and half of the city shall go forth into captivity, and the residue of the people shall not be cut off from the city.

Then shall the Lord go forth, and fight against those nations, as when he fought in the day of battle.

And his feet shall stand in that day upon the mount of Olives, which is before Jerusalem on the east, and the mount of Olives shall cleave in the midst thereof toward the east and toward the west, and there shall be a very great valley; and half of the mountain shall remove toward the north, and half of it toward the south.

And ye shall flee to the valley of the mountains; for the valley of the mountains shall reach unto Azal: yea, ye shall flee, like as ye fled from before the earthquake in the days of Uzziah king of Judah: and the Lord my God shall come, and all the saints with thee.

And it shall come to pass in that day, that the light shall not be clear, nor dark:

But it shall be one day which shall be known to the Lord, not day, nor night: but it shall come to pass, that at evening time it shall be light.

And it shall be in that day, that living waters shall go out from Jerusalem; half of them toward the former sea, and half of them toward the hinder sea: in summer and in winter shall it be.

And the Lord shall be king over all the earth: in that day shall there be one Lord, and his name one.

10 All the land shall be turned as a plain from Geba to Rimmon south of Jerusalem: and it shall be lifted up, and inhabited in her place, from Benjamin's gate unto the place of the first gate, unto the corner gate, and from the tower of Hananeel unto the king's winepresses.

11 And men shall dwell in it, and there shall be no more utter destruction; but Jerusalem shall be safely inhabited.

12 And this shall be the plague wherewith the Lord will smite all the people that have fought against Jerusalem; Their flesh shall consume away while they stand upon their feet, and their eyes shall consume away in their holes, and their tongue shall consume away in their mouth.

13 And it shall come to pass in that day, that a great tumult from the Lord shall be among them; and they shall lay hold every one on the hand of his neighbour, and his hand shall rise up against the hand of his neighbour.

14 And Judah also shall fight at Jerusalem; and the wealth of all the heathen round about shall be gathered together, gold, and silver, and apparel, in great abundance.

15 And so shall be the plague of the horse, of the mule, of the camel, and of the ass, and of all the beasts that shall be in these tents, as this plague.

16 And it shall come to pass, that every one that is left of all the nations which came against Jerusalem shall even go up from year to year to worship the King, the Lord of hosts, and to keep the feast of tabernacles.

17 And it shall be, that whoso will not come up of all the families of the earth unto Jerusalem to worship the King, the Lord of hosts, even upon them shall be no rain.

18 And if the family of Egypt go not up, and come not, that have no rain; there shall be the plague, wherewith the Lord will smite the heathen that come not up to keep the feast of tabernacles.

19 This shall be the punishment of Egypt, and the punishment of all nations that come not up to keep the feast of tabernacles.

20 In that day shall there be upon the bells of the horses, Holiness Unto The Lord; and the pots in the Lord's house shall be like the bowls before the altar.

21 Yea, every pot in Jerusalem and in Judah shall be holiness unto the Lord of hosts: and all they that sacrifice shall come and take of them, and seethe therein: and in that day there shall be no more the Canaanite in the house of the Lord of hosts.