Add parallel Print Page Options

Fún adarí orin. Ti Dafidi. Saamu.

139 Olúwa, ìwọ tí wádìí mi,
    ìwọ sì ti mọ̀ mí.
Ìwọ mọ̀ ìjókòó mi àti ìdìde mi,
    ìwọ mọ̀ èrò mi ní ọ̀nà jíjìn réré.
Ìwọ yí ipa ọ̀nà mi ká àti ìdùbúlẹ̀ mi,
    gbogbo ọ̀nà mi sì di mí mọ̀ fún ọ.
Nítorí tí kò sí ọ̀rọ̀ kan ní ahọ́n mi,
    kíyèsi i, Olúwa, ìwọ mọ̀ ọ́n pátápátá.
Ìwọ sé mi mọ́ lẹ́yìn àti níwájú,
    ìwọ sì fi ọwọ́ rẹ lé mi.
Irú ìmọ̀ yìí jẹ ohun ìyanu fún mi jù;
    ó ga, èmi kò le mọ̀ ọ́n.

Níbo ní èmi yóò gbé lọ kúrò ni ọwọ́ ẹ̀mí rẹ?
    Tàbí níbo ni èmi yóò sáré kúrò níwájú rẹ?
Bí èmi bá gòkè lọ sí ọ̀run, ìwọ wà níbẹ̀;
    bí èmí ba sì tẹ́ ẹní mi ní ipò òkú,
    kíyèsi i, ìwọ wà níbẹ̀ pẹ̀lú.
Èmi ìbá mú ìyẹ́ apá òwúrọ̀,
    kí èmi sì lọ jókòó ní ìhà òpin Òkun;
10 Àní, níbẹ̀ náà ni ọwọ́ rẹ̀ yóò fà mí
    ọwọ́ ọ̀tún rẹ yóò sì dì mímú.
11 Bí mo bá wí pé, “Ǹjẹ́ kí òkùnkùn kí ó bò mí mọ́lẹ̀;
    kí ìmọ́lẹ̀ kí ó di òru yí mi ká.”
12 Nítòótọ́ òkùnkùn kì í ṣú lọ́dọ̀ rẹ;
    ṣùgbọ́n òru tan ìmọ́lẹ̀ bí ọ̀sán;
    àti òkùnkùn àti ọ̀sán, méjèèjì bákan náà ní fún ọ.

13 Nítorí ìwọ ni ó dá ọkàn mi;
    ìwọ ni ó bò mí mọ́lẹ̀ nínú ìyá mi.
14 Èmi yóò yìn ọ, nítorí tẹ̀rù tẹ̀rù àti tìyanu tìyanu ní a dá mi;
    ìyanu ní iṣẹ́ rẹ;
    èyí nì ni ọkàn mi sì mọ̀ dájúdájú
15 Ẹ̀dá ara mi kò pamọ́ kúrò lọ́dọ̀ rẹ,
    nígbà tí a dá mi ní ìkọ̀kọ̀.
    Tí a sì ń ṣiṣẹ́ ní àràbarà ní ìhà ìsàlẹ̀ ilẹ̀ ayé,
16 ojú rẹ ti rí ohun ara mi
    nígbà tí a kò tí ì ṣe mí pé:
    àti nínú ìwé rẹ ni a ti kọ ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn sí,
ní ọjọ́ tí a dá wọn,
    nígbà tí wọn kò tilẹ̀ tí ì sí.
17 Ọlọ́run, èrò inú rẹ tí ṣe iyebíye tó fún mi,
    iye wọn ti pọ̀ tó!
18 Èmi ìbá kà wọ́n,
    wọ́n ju iyanrìn lọ ní iye:
nígbà tí mo bá jí,
    èmi yóò wà lọ́dọ̀ rẹ síbẹ̀.

19 Ọlọ́run ìbá jẹ́ pa àwọn ènìyàn búburú nítòótọ́;
    nítorí náà kúrò lọ́dọ̀ mi ẹ̀yin ọkùnrin ẹlẹ́jẹ̀.
20 Ẹni tí ń fi inú búburú sọ̀rọ̀ sí ọ,
    àwọn ọ̀tá rẹ ń pe orúkọ rẹ ní asán!
21 Olúwa, ǹjẹ́ èmi kò kórìíra àwọn tó kórìíra rẹ?
    Ǹjẹ́ inú mi kò a sì bàjẹ́ sí àwọn tí ó dìde sí ọ?
22 Èmi kórìíra wọn ní àkótán;
    èmi kà wọ́n sí ọ̀tá mi.
23 Ọlọ́run, wádìí mi, kí o sì mọ ọkàn mí;
    dán mi wò, kí o sì mọ ìrò inú mi
24 Kí ó sì wò ó bí ipa ọ̀nà búburú
    kan bá wà nínú mi kí ó sì
    fi ẹsẹ̀ mi lé ọ̀nà àìnípẹ̀kun.

Psalm 139

For the director of music. Of David. A psalm.

You have searched me,(A) Lord,
    and you know(B) me.
You know when I sit and when I rise;(C)
    you perceive my thoughts(D) from afar.
You discern my going out(E) and my lying down;
    you are familiar with all my ways.(F)
Before a word is on my tongue
    you, Lord, know it completely.(G)
You hem me in(H) behind and before,
    and you lay your hand upon me.
Such knowledge is too wonderful for me,(I)
    too lofty(J) for me to attain.

Where can I go from your Spirit?
    Where can I flee(K) from your presence?
If I go up to the heavens,(L) you are there;
    if I make my bed(M) in the depths, you are there.
If I rise on the wings of the dawn,
    if I settle on the far side of the sea,
10 even there your hand will guide me,(N)
    your right hand(O) will hold me fast.
11 If I say, “Surely the darkness will hide me
    and the light become night around me,”
12 even the darkness will not be dark(P) to you;
    the night will shine like the day,
    for darkness is as light to you.

13 For you created my inmost being;(Q)
    you knit me together(R) in my mother’s womb.(S)
14 I praise you(T) because I am fearfully and wonderfully made;
    your works are wonderful,(U)
    I know that full well.
15 My frame was not hidden from you
    when I was made(V) in the secret place,
    when I was woven together(W) in the depths of the earth.(X)
16 Your eyes saw my unformed body;
    all the days ordained(Y) for me were written in your book
    before one of them came to be.
17 How precious to me are your thoughts,[a](Z) God!(AA)
    How vast is the sum of them!
18 Were I to count them,(AB)
    they would outnumber the grains of sand(AC)
    when I awake,(AD) I am still with you.

19 If only you, God, would slay the wicked!(AE)
    Away from me,(AF) you who are bloodthirsty!(AG)
20 They speak of you with evil intent;
    your adversaries(AH) misuse your name.(AI)
21 Do I not hate those(AJ) who hate you, Lord,
    and abhor(AK) those who are in rebellion against you?
22 I have nothing but hatred for them;
    I count them my enemies.(AL)
23 Search me,(AM) God, and know my heart;(AN)
    test me and know my anxious thoughts.
24 See if there is any offensive way(AO) in me,
    and lead me(AP) in the way everlasting.

Footnotes

  1. Psalm 139:17 Or How amazing are your thoughts concerning me

139 O lord, thou hast searched me, and known me.

Thou knowest my downsitting and mine uprising, thou understandest my thought afar off.

Thou compassest my path and my lying down, and art acquainted with all my ways.

For there is not a word in my tongue, but, lo, O Lord, thou knowest it altogether.

Thou hast beset me behind and before, and laid thine hand upon me.

Such knowledge is too wonderful for me; it is high, I cannot attain unto it.

Whither shall I go from thy spirit? or whither shall I flee from thy presence?

If I ascend up into heaven, thou art there: if I make my bed in hell, behold, thou art there.

If I take the wings of the morning, and dwell in the uttermost parts of the sea;

10 Even there shall thy hand lead me, and thy right hand shall hold me.

11 If I say, Surely the darkness shall cover me; even the night shall be light about me.

12 Yea, the darkness hideth not from thee; but the night shineth as the day: the darkness and the light are both alike to thee.

13 For thou hast possessed my reins: thou hast covered me in my mother's womb.

14 I will praise thee; for I am fearfully and wonderfully made: marvellous are thy works; and that my soul knoweth right well.

15 My substance was not hid from thee, when I was made in secret, and curiously wrought in the lowest parts of the earth.

16 Thine eyes did see my substance, yet being unperfect; and in thy book all my members were written, which in continuance were fashioned, when as yet there was none of them.

17 How precious also are thy thoughts unto me, O God! how great is the sum of them!

18 If I should count them, they are more in number than the sand: when I awake, I am still with thee.

19 Surely thou wilt slay the wicked, O God: depart from me therefore, ye bloody men.

20 For they speak against thee wickedly, and thine enemies take thy name in vain.

21 Do not I hate them, O Lord, that hate thee? and am not I grieved with those that rise up against thee?

22 I hate them with perfect hatred: I count them mine enemies.

23 Search me, O God, and know my heart: try me, and know my thoughts:

24 And see if there be any wicked way in me, and lead me in the way everlasting.