Add parallel Print Page Options

Òun ó sì dá Israẹli ní ìdè
    kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ gbogbo.

Read full chapter

He himself will redeem(A) Israel
    from all their sins.(B)

Read full chapter

23 Wọn kì yóò sì tún fi àwọn òrìṣà wọn ba ara wọn jẹ́ mọ́, tàbí ohun ìríra wọn, tàbí ohun ìrékọjá wọn: ṣùgbọ́n èmi yóò gbà wọn là kúrò nínú gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ àgàbàgebè wọn, èmi yóò sì wẹ̀ wọn mọ́. Wọn yóò jẹ́ ènìyàn mi, Èmi yóò sì jẹ́ Ọlọ́run wọn.

Read full chapter

23 They will no longer defile(A) themselves with their idols and vile images or with any of their offenses, for I will save them from all their sinful backsliding,[a](B) and I will cleanse them. They will be my people, and I will be their God.(C)

Read full chapter

Footnotes

  1. Ezekiel 37:23 Many Hebrew manuscripts (see also Septuagint); most Hebrew manuscripts all their dwelling places where they sinned

(A)Nítorí pé ènìyàn mímọ́ ní ẹ jẹ́ fún Olúwa Ọlọ́run yín, nínú gbogbo ènìyàn tí ó wà lórí ilẹ̀ ayé, Ọlọ́run ti yàn yín láti jẹ́ ìṣúra iyebíye rẹ̀.

Read full chapter

for you are a people holy(A) to the Lord your God.(B) Out of all the peoples on the face of the earth, the Lord has chosen you to be his treasured possession.(C)

Read full chapter