Add parallel Print Page Options

Ikú nípasẹ̀ Adamu, iyè nípasẹ̀ Jesu

12 (A)Nítorí gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ṣẹ̀ ti tipa ọ̀dọ̀ ènìyàn kan wọ ayé, àti ikú nípa ẹ̀ṣẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni ikú sì kọjá sórí ènìyàn gbogbo, láti ọ̀dọ̀ ẹni tí gbogbo ènìyàn ti dẹ́ṣẹ̀:

Read full chapter

Death Through Adam, Life Through Christ

12 Therefore, just as sin entered the world through one man,(A) and death through sin,(B) and in this way death came to all people, because all sinned(C)

Read full chapter

21 (A)Pé, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ṣẹ̀ ti jẹ ọba nípa ikú bẹ́ẹ̀ ni kí oore-ọ̀fẹ́ sì lè jẹ ọba nípa òdodo títí ìyè àìnípẹ̀kun nípasẹ̀ Jesu Kristi Olúwa wa.

Read full chapter

21 so that, just as sin reigned in death,(A) so also grace(B) might reign through righteousness to bring eternal life(C) through Jesus Christ our Lord.

Read full chapter

Kí a má ṣe tàn yín jẹ; a kò lè gan Ọlọ́run: nítorí ohunkóhun tí ènìyàn bá fúnrúgbìn, òhun ni yóò sì ká. Nítorí ẹni tí ó bá ń fúnrúgbìn sípa ti ara yóò ká ìdíbàjẹ́ ti ara ṣùgbọ́n ẹni tí ń fúnrúgbìn sípa ti ẹ̀mí yóò ti inú ẹ̀mí ká ìyè àìnípẹ̀kun.

Read full chapter

Do not be deceived:(A) God cannot be mocked. A man reaps what he sows.(B) Whoever sows to please their flesh,(C) from the flesh will reap destruction;(D) whoever sows to please the Spirit, from the Spirit will reap eternal life.(E)

Read full chapter