Add parallel Print Page Options

19 (A)nípa agbára iṣẹ́ ààmì àti iṣẹ́ ìyanu, nípa agbára Ẹ̀mí Ọlọ́run, tó bẹ́ẹ̀ láti Jerusalẹmu àti yíkákiri, àní títí fi dé Illirikoni, mo ti polongo ìhìnrere Kristi ní ẹ̀kúnrẹ́rẹ́.

Read full chapter

19 by the power of signs and wonders,(A) through the power of the Spirit of God.(B) So from Jerusalem(C) all the way around to Illyricum, I have fully proclaimed the gospel of Christ.(D)

Read full chapter

20 Nítorí ìjọba Ọlọ́run kì í ṣe nínú ọ̀rọ̀, bí kò ṣe nínú agbára.

Read full chapter

20 For the kingdom of God is not a matter of(A) talk but of power.(B)

Read full chapter