Add parallel Print Page Options

14 Nítorí Ọlọ́run yóò ṣe ìdájọ́ olúkúlùkù iṣẹ́
    àti ohun ìkọ̀kọ̀,
    kì bá à ṣe rere kì bá à ṣe búburú.

Read full chapter

14 For God will bring every deed into judgment,(A)
    including every hidden thing,(B)
    whether it is good or evil.

Read full chapter

25 Ǹjẹ́ fún ẹni tí ó ní agbára láti fi ẹsẹ̀ yín múlẹ̀ nípa ìhìnrere mi àti ìpolongo Jesu Kristi, gẹ́gẹ́ bí ìṣípayá ohun ìjìnlẹ̀ tí a ti pamọ́ láti ìgbà ayérayé,

Read full chapter

25 Now to him who is able(A) to establish you in accordance with my gospel,(B) the message I proclaim about Jesus Christ, in keeping with the revelation of the mystery(C) hidden for long ages past,

Read full chapter

(A)Nítorí náà, kí ẹ má ṣe ṣe ìdájọ́ ohunkóhun, kí Olúwa tó padà dé, ẹni tí yóò mú ohunkóhun tí ó fi ara sin wá sí ìmọ́lẹ̀, tí yóò sì fi ìmọ̀ ọkàn ènìyàn hàn, nígbà náà ni olúkúlùkù yóò sì ní ìyìn tirẹ̀ lọ́dọ̀ Ọlọ́run.

Read full chapter

Therefore judge nothing(A) before the appointed time; wait until the Lord comes.(B) He will bring to light(C) what is hidden in darkness and will expose the motives of the heart. At that time each will receive their praise from God.(D)

Read full chapter