Add parallel Print Page Options

Ìbùkún àlùfáà

22 Olúwa sọ fún Mose pé, 23 “Sọ fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ pé, ‘Báyìí ni kí ẹ ṣe máa súre fún àwọn ọmọ Israẹli. Ẹ sọ fún wọn pé:

24 “ ‘ “Kí Olúwa bùkún un yín
    Kí ó sì pa yín mọ́.
25 Olúwa kí o mú ojú rẹ̀ kí ó mọ́lẹ̀ sí i yín lára.
    Kí ó sì ṣàánú fún un yín.
26 Olúwa bojú wò yín;
    Kí ó sì fún un yín ní àlàáfíà.” ’

Read full chapter