Add parallel Print Page Options

11 Mo sì wí fún yín, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni yóò ti ìhà ìlà-oòrùn àti ìhà ìwọ̀-oòrùn wá, wọ́n á sì bá Abrahamu àti Isaaki àti Jakọbu jẹun ní ìjọba ọ̀run.

Read full chapter

11 I say to you that many will come from the east and the west,(A) and will take their places at the feast with Abraham, Isaac and Jacob in the kingdom of heaven.(B)

Read full chapter

29 Wọn ó sì ti ilẹ̀ ìlà-oòrùn, àti ìwọ̀-oòrùn wá, àti láti àríwá, àti gúúsù wá, wọn ó sì jókòó ní ìjọba Ọlọ́run.

Read full chapter

29 People will come from east and west(A) and north and south, and will take their places at the feast in the kingdom of God.

Read full chapter