Add parallel Print Page Options

Ìtọrẹ àánú

(A)“Ẹ kíyèsára kí ẹ má ṣe iṣẹ́ rere yín níwájú àwọn ènìyàn nítorí kí a le rí yín, Bí ẹ bá ṣe bẹ́ẹ̀, ẹ̀yin kò ni èrè kankan lọ́dọ̀ Baba yín ní ọ̀run.

Read full chapter

Giving to the Needy

“Be careful not to practice your righteousness in front of others to be seen by them.(A) If you do, you will have no reward from your Father in heaven.

Read full chapter

16 Bákan náà, ẹ jẹ́ kí ìmọ́lẹ̀ yín kí ó mọ́lẹ̀ níwájú ènìyàn, kí wọ́n lè máa rí iṣẹ́ rere yín, kí wọn lè máa yin baba yín tí ń bẹ ní ọ̀run lógo.

Read full chapter

16 In the same way, let your light shine before others,(A) that they may see your good deeds(B) and glorify(C) your Father in heaven.

Read full chapter

Ṣíṣe èyí yóò wà fún ààmì ní ọwọ́ rẹ, àti bí ààmì ìrántí ni iwájú orí rẹ, tí yóò máa rán ọ létí òfin Olúwa ní ẹnu rẹ. Nítorí Olúwa mú ọ jáde láti ilẹ̀ Ejibiti pẹ̀lú ọwọ́ agbára ńlá rẹ̀.

Read full chapter

This observance will be for you like a sign on your hand(A) and a reminder on your forehead(B) that this law of the Lord is to be on your lips. For the Lord brought you out of Egypt with his mighty hand.(C)

Read full chapter

(A)Ẹ so wọ́n sí ọwọ́ yín fún ààmì, ẹ so ó mọ́ iwájú orí yín.

Read full chapter

Tie them as symbols on your hands and bind them on your foreheads.(A)

Read full chapter

20 Sì kíyèsi i, obìnrin kan ti ó ní ìsun ẹ̀jẹ̀ ní ọdún méjìlá, ó wá lẹ́yìn rẹ̀, ó fi ọwọ́ kan ìṣẹ́tí aṣọ rẹ̀.

Read full chapter

20 Just then a woman who had been subject to bleeding for twelve years came up behind him and touched the edge of his cloak.(A)

Read full chapter