Add parallel Print Page Options

38 (A)Nítorí náà, bí ẹnikẹ́ni bá tijú àti gbà mí tàbí ọ̀rọ̀ mi nínú ìran panṣágà àti ẹlẹ́ṣẹ̀ yìí, tí ó kún fún àìgbàgbọ́ àti ẹ̀ṣẹ̀ báyìí, Ọmọ Ènìyàn yóò tijú rẹ̀ nígbà tí ó bá padà dé nínú ògo Baba rẹ̀, pẹ̀lú àwọn angẹli mímọ́.”

Read full chapter

38 If anyone is ashamed of me and my words in this adulterous and sinful generation, the Son of Man(A) will be ashamed of them(B) when he comes(C) in his Father’s glory with the holy angels.”

Read full chapter

26 (A)Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá tijú mi, àti ọ̀rọ̀ mi, òun ni ọmọ ènìyàn yóò tijú rẹ̀ nígbà tí ó bá dé inú ògo tirẹ̀, àti ti baba rẹ̀, àti ti àwọn angẹli mímọ́.

Read full chapter

26 Whoever is ashamed of me and my words, the Son of Man will be ashamed of them(A) when he comes in his glory and in the glory of the Father and of the holy angels.(B)

Read full chapter

12 Bí àwa bá faradà,
    àwa ó sì bá a jẹ ọba:
Bí àwa bá sẹ́ ẹ,
    òun náà yóò sì sẹ́ wa.

Read full chapter

12 if we endure,
    we will also reign with him.(A)
If we disown him,
    he will also disown us;(B)

Read full chapter