Luku 7:39
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
39 (A)Nígbà tí Farisi tí ó pè é sì rí i, ó wí nínú ara rẹ̀ pé, “Ọkùnrin yìí ìbá ṣe wòlíì, ìbá mọ ẹni àti irú ẹni tí obìnrin yìí jẹ́ tí ń fi ọwọ́ kàn an, nítorí ẹlẹ́ṣẹ̀ ni.”
Read full chapter
Luke 7:39
New International Version
39 When the Pharisee who had invited him saw this, he said to himself, “If this man were a prophet,(A) he would know who is touching him and what kind of woman she is—that she is a sinner.”
Luku 24:19
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
19 (A)Ó sì bi wọ́n pé, “Kín ni?”
Wọ́n sì wí fún un pé, “Ní ti Jesu ti Nasareti, ẹni tí ó jẹ́ wòlíì, tí ó pọ̀ ní ìṣe àti ní ọrọ̀ níwájú Ọlọ́run àti gbogbo ènìyàn,
Read full chapter
Luke 24:19
New International Version
19 “What things?” he asked.
“About Jesus of Nazareth,”(A) they replied. “He was a prophet,(B) powerful in word and deed before God and all the people.
Matiu 21:11
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
11 (A)Ọ̀pọ̀ ènìyàn sì dáhùn pé, “Èyí ni Jesu, wòlíì náà láti Nasareti ti Galili.”
Read full chapter
Matthew 21:11
New International Version
11 The crowds answered, “This is Jesus, the prophet(A) from Nazareth in Galilee.”
Johanu 6:14
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
14 (A)Nítorí náà nígbà tí àwọn ọkùnrin náà rí iṣẹ́ ààmì tí Jesu ṣe, wọ́n wí pé, “Lóòótọ́ èyí ni wòlíì náà tí ń bọ̀ wá sí ayé.”
Read full chapter
John 6:14
New International Version
14 After the people saw the sign(A) Jesus performed, they began to say, “Surely this is the Prophet who is to come into the world.”(B)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.
Holy Bible, New International Version®, NIV® Copyright ©1973, 1978, 1984, 2011 by Biblica, Inc.® Used by permission. All rights reserved worldwide.
NIV Reverse Interlinear Bible: English to Hebrew and English to Greek. Copyright © 2019 by Zondervan.