Add parallel Print Page Options

18 (A)Ṣùgbọ́n irun orí yín kan kì yóò ṣègbé.

Read full chapter

18 But not a hair of your head will perish.(A)

Read full chapter

34 Nítorí náà mo bẹ̀ yín, kí ẹ jẹun díẹ̀, nítorí èyí ni fún ìgbàlà yín: nítorí irun kan kí yóò gé kúrò lórí ẹnìkan nínú yín.”

Read full chapter

34 Now I urge you to take some food. You need it to survive. Not one of you will lose a single hair from his head.”(A)

Read full chapter

12 Ǹjẹ́ mélòó mélòó ní ènìyàn ní iye lórí ju àgùntàn kan lọ! Nítorí náà ó yẹ láti ṣe rere ní ọjọ́ ìsinmi.”

Read full chapter

12 How much more valuable is a person than a sheep!(A) Therefore it is lawful to do good on the Sabbath.”

Read full chapter