Add parallel Print Page Options

22 (A)“ ‘Nígbà tí ẹ bá kórè ilẹ̀ yín ẹ má ṣe kórè dé ìkangun oko yín, tàbí kí ẹ padà gé èyí tí ó ṣẹ́kù sílẹ̀ nínú ìkórè yín. Ẹ fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn tálákà àti àwọn àlejò: Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’ ”

Read full chapter

22 “‘When you reap the harvest(A) of your land, do not reap to the very edges of your field or gather the gleanings of your harvest.(B) Leave them for the poor and for the foreigner residing among you.(C) I am the Lord your God.’”

Read full chapter

20 Nígbà tí o bá ń gun igi olifi lára àwọn igi i rẹ, má ṣe padà lọ sí ẹ̀ka náà ní ìgbà kejì. Fi èyí tí ó kù fún àlejò, aláìní baba àti opó.

Read full chapter

20 When you beat the olives from your trees, do not go over the branches a second time.(A) Leave what remains for the foreigner, the fatherless and the widow.

Read full chapter

21 Nígbà tí ìwọ bá kórè èso àjàrà nínú ọgbà àjàrà rẹ, má ṣe lọ sí ọgbà náà mọ́. Fi èyí tí ó kù fún àlejò, aláìní baba àti opó.

Read full chapter

21 When you harvest the grapes in your vineyard, do not go over the vines again. Leave what remains for the foreigner, the fatherless and the widow.

Read full chapter