Add parallel Print Page Options

(A)“ ‘Ẹnìkọ̀ọ̀kan yín gbọdọ̀ bọ̀wọ̀ fún ìyá àti baba rẹ̀, kí ẹ sì ya ọjọ́ ìsinmi mi sí mímọ́. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.

Read full chapter

“‘Each of you must respect your mother and father,(A) and you must observe my Sabbaths.(B) I am the Lord your God.(C)

Read full chapter

16 (A)(B) Bọ̀wọ̀ fún baba òun ìyá rẹ, bí Olúwa Ọlọ́run yín ti pàṣẹ fún ọ, kí ọjọ́ rẹ kí ó lè pẹ́, àti kí ó lè dára fún ọ ní ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run rẹ fi fún ọ.

Read full chapter

16 “Honor your father(A) and your mother,(B) as the Lord your God has commanded you, so that you may live long(C) and that it may go well with you in the land the Lord your God is giving you.

Read full chapter

Nítorí Ọlọ́run wí pé, ‘Bọ̀wọ̀ fún Baba òun ìyá rẹ,’ àti pé, ‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ ọ̀rọ̀-òdì sí baba tàbí ìyá rẹ̀, ní láti kú.’

Read full chapter

For God said, ‘Honor your father and mother’[a](A) and ‘Anyone who curses their father or mother is to be put to death.’[b](B)

Read full chapter

Footnotes

  1. Matthew 15:4 Exodus 20:12; Deut. 5:16
  2. Matthew 15:4 Exodus 21:17; Lev. 20:9

10 (A)Mose fún un yín ní òfin yìí láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run pé, ‘Bọ̀wọ̀ fún baba òun ìyá rẹ.’ Ó tún sọ pé, ‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ̀rọ̀ aburú sí baba tàbí ìyá rẹ̀ ní láti kú ni.’

Read full chapter

10 For Moses said, ‘Honor your father and mother,’[a](A) and, ‘Anyone who curses their father or mother is to be put to death.’[b](B)

Read full chapter

Footnotes

  1. Mark 7:10 Exodus 20:12; Deut. 5:16
  2. Mark 7:10 Exodus 21:17; Lev. 20:9

(A)“Bọ̀wọ̀ fún baba àti ìyá rẹ,” èyí tí í ṣe òfin kìn-ín-ní pẹ̀lú ìlérí,

Read full chapter

“Honor your father and mother”—which is the first commandment with a promise—

Read full chapter