Font Size
Johanu 7:20
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Johanu 7:20
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
20 (A)Ìjọ ènìyàn dáhùn, wọ́n sì wí pé, “Ìwọ ní ẹ̀mí èṣù: Ta ni ń wá ọ̀nà láti pa ọ́?”
Read full chapter
Johanu 8:48
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Johanu 8:48
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Jesu béèrè nípa ohun tí n ṣe ti ara rẹ̀
48 (A)Àwọn Júù dáhùn wọ́n sì wí fún un pé, “Àwa kò wí nítòótọ́ pé, ará Samaria ni ìwọ jẹ́, àti pé ìwọ ní ẹ̀mí èṣù?”
Read full chapter
Matiu 11:18
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Matiu 11:18
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
18 Nítorí Johanu wá kò bá a yín jẹ bẹ́ẹ̀ ni kò mu, ẹ̀yin sì wí pé, ‘Ó ní ẹ̀mí èṣù.’
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.