Add parallel Print Page Options

15 (A)Ẹ̀yin ń ṣe ìdájọ́ nípa ti ara; èmi kò ṣe ìdájọ́ ẹnikẹ́ni.

Read full chapter

15 You judge by human standards;(A) I pass judgment on no one.(B)

Read full chapter

47 (A)“Bí ẹnikẹ́ni bá sì gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, tí kò sì pa wọ́n mọ́, èmi kì yóò ṣe ìdájọ́ rẹ̀ nítorí tí èmi kò wá láti ṣe ìdájọ́ ayé, bí kò ṣe láti gba ayé là.

Read full chapter

47 “If anyone hears my words but does not keep them, I do not judge that person. For I did not come to judge the world, but to save the world.(A)

Read full chapter

10 Nítorí Ọmọ Ènìyàn dé láti wá àwọn tí ó nù kiri, àti láti gbà wọ́n là.”

Read full chapter

10 For the Son of Man came to seek and to save the lost.”(A)

Read full chapter

14 (A)Àwa tí rí, a sì jẹ́rìí pé Baba rán Ọmọ rẹ̀ láti jẹ́ Olùgbàlà fún aráyé.

Read full chapter

14 And we have seen and testify(A) that the Father has sent his Son to be the Savior of the world.(B)

Read full chapter