Add parallel Print Page Options

45 (A)“Ẹ má ṣe rò pé, èmi ó fi yín sùn lọ́dọ̀ Baba: ẹni tí ń fi yín sùn wà, àní Mose, ẹni tí ẹ̀yin gbẹ́kẹ̀lé. 46 Nítorí pé ẹ̀yin ìbá gba Mose gbọ́, ẹ̀yin ìbá gbà mí gbọ́: nítorí ó kọ ìwé nípa tèmi. 47 (B)Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin kò bá gba ìwé rẹ̀ gbọ́, ẹ̀yin ó ti ṣe gbà ọ̀rọ̀ mi gbọ́?”

Read full chapter

45 “But do not think I will accuse you before the Father. Your accuser is Moses,(A) on whom your hopes are set.(B) 46 If you believed Moses, you would believe me, for he wrote about me.(C) 47 But since you do not believe what he wrote, how are you going to believe what I say?”(D)

Read full chapter

21 Nítorí òfin Mose nígbà àtijọ́ ṣá ní a ti ń wàásù rẹ̀, ni ìlú gbogbo, a máa ń kà á nínú Sinagọgu ni ọjọọjọ́ ìsinmi.”

Read full chapter

21 For the law of Moses has been preached in every city from the earliest times and is read in the synagogues on every Sabbath.”(A)

Read full chapter

17 A sì fi ìwé wòlíì Isaiah fún un. Nígbà tí ó sì ṣí ìwé náà, ó rí ibi tí a gbé kọ ọ́ pé:

Read full chapter

17 and the scroll of the prophet Isaiah was handed to him. Unrolling it, he found the place where it is written:

Read full chapter