Add parallel Print Page Options

Nítorí náà, ó sáré, ó sì tọ Simoni Peteru àti ọmọ-ẹ̀yìn mìíràn wá, ẹni tí Jesu fẹ́ràn, ó sì wí fún wọn pé, “Wọ́n ti gbé Olúwa kúrò nínú ibojì, àwa kò sì mọ ibi tí wọ́n gbé tẹ́ ẹ sí.”

Read full chapter

So she came running to Simon Peter and the other disciple, the one Jesus loved,(A) and said, “They have taken the Lord out of the tomb, and we don’t know where they have put him!”(B)

Read full chapter