Add parallel Print Page Options

16 (A)Nígbà náà èmi yóò wá béèrè lọ́wọ́ Baba. Òun yóò sì fún yín ní olùtùnú mìíràn. Olùtùnú náà yóò máa bá yín gbé títí láé

Read full chapter

16 And I will ask the Father, and he will give you another advocate(A) to help you and be with you forever—

Read full chapter

26 Ṣùgbọ́n Olùtùnú náà, Ẹ̀mí Mímọ́, ẹni tí Baba yóò rán ní orúkọ mi, òun ni yóò kọ́ yín ní ohun gbogbo, yóò sì rán yín létí ohun gbogbo tí mo ti sọ fún yín.

Read full chapter

26 But the Advocate,(A) the Holy Spirit, whom the Father will send in my name,(B) will teach you all things(C) and will remind you of everything I have said to you.(D)

Read full chapter

(A)Ṣùgbọ́n òtítọ́ ni èmi ń sọ fún yín; àǹfààní ni yóò jẹ́ fún yín bí èmi bá lọ: nítorí bí èmi kò bá lọ, Olùtùnú kì yóò tọ̀ yín wá; ṣùgbọ́n bí mo bá lọ, èmi ó rán an sí yín.

Read full chapter

But very truly I tell you, it is for your good that I am going away. Unless I go away, the Advocate(A) will not come to you; but if I go, I will send him to you.(B)

Read full chapter

(A)Ẹ̀yin ọmọ mi ọ̀wọ́n, mo kọ ìwé nǹkan wọ̀nyí sí yín, kí ẹ̀yin má bà á dẹ́ṣẹ̀. Ṣùgbọ́n bí ẹnikẹ́ni bá sì dẹ́ṣẹ̀, àwa ni alágbàwí lọ́dọ̀ Baba: Jesu Kristi, olódodo nìkan.

Read full chapter

My dear children,(A) I write this to you so that you will not sin. But if anybody does sin, we have an advocate(B) with the Father—Jesus Christ, the Righteous One.

Read full chapter

Nítorí pé àwọn mẹ́ta ni ó ń jẹ́rìí.

Read full chapter

For there are three(A) that testify:

Read full chapter