Font Size
Johanu 11:55
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Johanu 11:55
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
55 (A)Àjọ ìrékọjá àwọn Júù sì súnmọ́ etílé: ọ̀pọ̀lọpọ̀ láti ìgbèríko sì gòkè lọ sí Jerusalẹmu ṣáájú ìrékọjá, láti ya ara wọn sí mímọ́.
Read full chapter
Johanu 12:23
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Johanu 12:23
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
23 (A)Jesu sì dá wọn lóhùn pé, “Wákàtí náà dé, tí a ó ṣe Ọmọ ènìyàn lógo.
Read full chapter
Johanu 16:28
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Johanu 16:28
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
28 Mo ti ọ̀dọ̀ Baba jáde wá, mo sì wá sí ayé: àti nísinsin yìí mo fi ayé sílẹ̀, mo sì lọ sọ́dọ̀ Baba.”
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.