Add parallel Print Page Options

(A)Nínú rẹ̀ ni ìyè wà, ìyè yìí náà sì ni ìmọ́lẹ̀ aráyé,

Read full chapter

26 Nítorí pé gẹ́gẹ́ bí Baba ti ní ìyè nínú ara rẹ̀; gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni ó sì fi fún ọmọ láti ní ìyè nínú ara rẹ̀;

Read full chapter

26 For as the Father has life in himself, so he has granted the Son also to have life(A) in himself.

Read full chapter

18 Èmi ni ẹni tí ó ń bẹ láààyè, tí ó sì ti kú; sì kíyèsi i, èmi sì ń bẹ láààyè sí i títí láé! Mo sì ní kọ́kọ́rọ́ ikú àti ti ipò òkú lọ́wọ́.

Read full chapter

18 I am the Living One; I was dead,(A) and now look, I am alive for ever and ever!(B) And I hold the keys of death and Hades.(C)

Read full chapter