Font Size
Johanu 1:4
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Johanu 1:4
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
4 (A)Nínú rẹ̀ ni ìyè wà, ìyè yìí náà sì ni ìmọ́lẹ̀ aráyé,
Read full chapter
Johanu 5:26
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Johanu 5:26
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
26 Nítorí pé gẹ́gẹ́ bí Baba ti ní ìyè nínú ara rẹ̀; gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni ó sì fi fún ọmọ láti ní ìyè nínú ara rẹ̀;
Read full chapter
Ìfihàn 1:18
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Ìfihàn 1:18
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
18 Èmi ni ẹni tí ó ń bẹ láààyè, tí ó sì ti kú; sì kíyèsi i, èmi sì ń bẹ láààyè sí i títí láé! Mo sì ní kọ́kọ́rọ́ ikú àti ti ipò òkú lọ́wọ́.
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.