Add parallel Print Page Options

21 wí pé:

“Ní ìhòhò ní mo ti inú ìyá mi jáde wá,
    ni ìhòhò ní èmi yóò sì tún padà lọ.
Olúwa fi fún ni, Olúwa sì gbà á lọ,
    ìbùkún ni fún orúkọ Olúwa.”

22 Nínú gbogbo èyí Jobu kò ṣẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò sì fi òmùgọ̀ pe Ọlọ́run lẹ́jọ́.

Read full chapter

21 and said:

“Naked I came from my mother’s womb,
    and naked I will depart.[a](A)
The Lord gave and the Lord has taken away;(B)
    may the name of the Lord be praised.”(C)

22 In all this, Job did not sin by charging God with wrongdoing.(D)

Read full chapter

Footnotes

  1. Job 1:21 Or will return there

10 Ṣùgbọ́n ó dá a lóhùn pé, “Ìwọ sọ̀rọ̀ bí ọ̀kan lára àwọn aṣiwèrè obìnrin ti í sọ̀rọ̀; há bà! Àwa yóò ha gba ìre lọ́wọ́ Ọlọ́run, kí a má sì gba ibi?”

Nínú gbogbo èyí, Jobu kò fi ètè rẹ̀ ṣẹ̀.

Read full chapter

10 He replied, “You are talking like a foolish[a] woman. Shall we accept good from God, and not trouble?”(A)

In all this, Job did not sin in what he said.(B)

Read full chapter

Footnotes

  1. Job 2:10 The Hebrew word rendered foolish denotes moral deficiency.

(A)Olúwa ni aláàánú àti olóore,
    ó lọ́ra láti bínú, ó sì pọ̀ ní ìfẹ́.

Read full chapter

The Lord is compassionate and gracious,(A)
    slow to anger, abounding in love.

Read full chapter

Ó ti ṣe iṣẹ́ ìyanu rẹ̀, láti máa rántí:
    Olúwa ni olóore-ọ̀fẹ́ àti pé ó kún fún àánú.

Read full chapter

He has caused his wonders to be remembered;
    the Lord is gracious and compassionate.(A)

Read full chapter