Font Size
Jeremiah 50:8
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Jeremiah 50:8
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
8 “Jáde kúrò ní Babeli,
ẹ fi ilẹ̀ àwọn ará Kaldea sílẹ̀,
kí ẹ sì jẹ́ bí òbúkọ níwájú agbo ẹran.
2 Kọrinti 6:17
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
2 Kọrinti 6:17
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
17 (A)Nítorí náà,
“Ẹ jáde kúrò láàrín wọn,
kí ẹ sì yá ara yín si ọ̀tọ̀,
ni Olúwa wí.
Ki ẹ má ṣe fi ọwọ́ kan ohun àìmọ́;
Èmi ó sì gbà yín.”
Ìfihàn 18:4
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Ìfihàn 18:4
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
4 (A)Mo sì gbọ́ ohùn mìíràn láti ọ̀run wá, wí pé:
“ ‘Ẹ ti inú rẹ̀ jáde, ẹ̀yin ènìyàn mi,’
kí ẹ ma bá a ṣe alábápín nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀,
kí ẹ ma bà á sì ṣe gbà nínú ìyọnu rẹ̀.
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.