Add parallel Print Page Options

“Jáde kúrò ní Babeli,
    ẹ fi ilẹ̀ àwọn ará Kaldea sílẹ̀,
    kí ẹ sì jẹ́ bí òbúkọ níwájú agbo ẹran.

Read full chapter

17 (A)Nítorí náà,

“Ẹ jáde kúrò láàrín wọn,
    kí ẹ sì yá ara yín si ọ̀tọ̀,
    ni Olúwa wí.
Ki ẹ má ṣe fi ọwọ́ kan ohun àìmọ́;
    Èmi ó sì gbà yín.”

Read full chapter

(A)Mo sì gbọ́ ohùn mìíràn láti ọ̀run wá, wí pé:

“ ‘Ẹ ti inú rẹ̀ jáde, ẹ̀yin ènìyàn mi,’
    kí ẹ ma bá a ṣe alábápín nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀,
    kí ẹ ma bà á sì ṣe gbà nínú ìyọnu rẹ̀.

Read full chapter