Add parallel Print Page Options

(A)“Ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí,
    “tí Èmi yóò gbé ẹ̀ka òdodo dìde fún Dafidi,
ọba tí yóò lo ìjọba pẹ̀lú ọgbọ́n
    tí yóò sì ṣe òdodo àti ohun tí ó yẹ lórí ilẹ̀ náà.

Read full chapter

“The days are coming,” declares the Lord,
    “when I will raise up for David[a] a righteous Branch,(A)
a King(B) who will reign(C) wisely
    and do what is just and right(D) in the land.

Read full chapter

Footnotes

  1. Jeremiah 23:5 Or up from David’s line

Ẹ̀ka Olúwa náà

(A)Ní ọjọ́ náà, ẹ̀ka Olúwa yóò ní ẹwà àti ògo, èso ilẹ̀ náà yóò sì jẹ́ ìgbéraga àti ògo àwọn ti ó sálà ní Israẹli.

Read full chapter

The Branch of the Lord

In that day(A) the Branch of the Lord(B) will be beautiful(C) and glorious, and the fruit(D) of the land will be the pride and glory(E) of the survivors(F) in Israel.

Read full chapter

(A)‘Gbọ́, ìwọ Joṣua olórí àlùfáà, ìwọ, àti àwọn ẹgbẹ́ rẹ tí ó jókòó níwájú rẹ: nítorí ẹni ìyanu ni wọ́n: nítorí kíyèsi i, èmi yóò mú ìránṣẹ́ mi, Ẹ̀ka náà wá.

Read full chapter

“‘Listen, High Priest(A) Joshua, you and your associates seated before you, who are men symbolic(B) of things to come: I am going to bring my servant, the Branch.(C)

Read full chapter

12 (A)Sì sọ fún un pé: ‘Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ wí pé, wo ọkùnrin náà ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Ẹ̀ka; yóò sì yọ ẹ̀ka láti abẹ́ rẹ̀ wá, yóò si kọ́ tẹmpili Olúwa wa.

Read full chapter

12 Tell him this is what the Lord Almighty says: ‘Here is the man whose name is the Branch,(A) and he will branch out from his place and build the temple of the Lord.(B)

Read full chapter