Add parallel Print Page Options

A bí ọmọ kan fún wa

(A)Síbẹ̀síbẹ̀, kò ní sí ìpòrúru kankan mọ́ fún àwọn tí ó wà nínú ìbànújẹ́. Nígbà kan rí ó rẹ ilẹ̀ Sebuluni sílẹ̀ àti ilẹ̀ Naftali pẹ̀lú, ṣùgbọ́n ní ọjọ́ iwájú, yóò bu ọ̀wọ̀ fún Galili ti àwọn aláìkọlà, ní ọ̀nà Òkun, ní ẹ̀gbẹ̀ẹ̀gbẹ́ Jordani.

Àwọn ènìyàn tí ń rìn nínú òkùnkùn
    ti rí ìmọ́lẹ̀ ńlá;
Lórí àwọn tí ń gbé nínú ilẹ̀ òjìji ikú,
    ní ara wọn ni ìmọ́lẹ̀ mọ́ sí.

Read full chapter

[a]Nevertheless, there will be no more gloom(A) for those who were in distress. In the past he humbled the land of Zebulun and the land of Naphtali,(B) but in the future he will honor Galilee of the nations, by the Way of the Sea, beyond the Jordan—

The people walking in darkness(C)
    have seen a great light;(D)
on those living in the land of deep darkness(E)
    a light has dawned.(F)

Read full chapter

Footnotes

  1. Isaiah 9:1 In Hebrew texts 9:1 is numbered 8:23, and 9:2-21 is numbered 9:1-20.