Add parallel Print Page Options

19 (A)ní dídá ìyìn sí ètè àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ ní Israẹli.
    Àlàáfíà, àlàáfíà fún àwọn tí ó wà lókèèrè àti nítòsí,”
    ni Olúwa wí, “Àti pé Èmi yóò wo wọ́n sàn.”

Read full chapter

19     creating praise on their lips.(A)
Peace, peace,(B) to those far and near,”(C)
    says the Lord. “And I will heal them.”

Read full chapter

32 (A)Yóò sí ṣe, ẹnikẹ́ni tí ó ba ké pè
    orúkọ Olúwa ní a ó gbàlà:
nítorí ní òkè Sioni àti ní Jerusalẹmu
    ní ìgbàlà yóò gbé wà,
    Olúwa ti wí,
àti nínú àwọn
    ìyókù tí Olúwa yóò pè.

Read full chapter

32 And everyone who calls
    on the name of the Lord(A) will be saved;(B)
for on Mount Zion(C) and in Jerusalem
    there will be deliverance,(D)
    as the Lord has said,
even among the survivors(E)
    whom the Lord calls.[a](F)

Read full chapter

Footnotes

  1. Joel 2:32 In Hebrew texts 2:28-32 is numbered 3:1-5.