Add parallel Print Page Options

12 (A)Nítorí náà èmi yóò fún un ní ìpín pẹ̀lú àwọn ẹni ńlá
    òun yóò sì pín ìkógun pẹ̀lú àwọn alágbára,
nítorí pé òun jọ̀wọ́ ẹ̀mí rẹ̀ fún ikú,
    tí a sì kà á mọ́ àwọn alárékọjá.
Nítorí ó ru ẹ̀ṣẹ̀ ọ̀pọ̀lọpọ̀,
    ó sì ṣe ìlàjà fún àwọn alárékọjá.

Read full chapter

12 Therefore I will give him a portion among the great,[a](A)
    and he will divide the spoils(B) with the strong,[b]
because he poured out his life unto death,(C)
    and was numbered with the transgressors.(D)
For he bore(E) the sin of many,(F)
    and made intercession(G) for the transgressors.

Read full chapter

Footnotes

  1. Isaiah 53:12 Or many
  2. Isaiah 53:12 Or numerous

(A)Ṣùgbọ́n a sá a lọ́gbẹ́ nítorí àìṣedéédéé wa
    a pa á lára nítorí àìṣòdodo wa;
ìjìyà tí ó mú àlàáfíà wá fún wa wà lórí i rẹ̀,
    àti nípa ọgbẹ́ rẹ̀ ni a fi mú wa láradá.
Gbogbo wa bí àgùntàn, ti ṣìnà lọ,
    ẹnìkọ̀ọ̀kan wa ti yà sí ọ̀nà ara rẹ̀;
Olúwa sì ti gbé e ka orí ara rẹ̀
    gbogbo àìṣedéédéé wa.

Read full chapter

But he was pierced(A) for our transgressions,(B)
    he was crushed(C) for our iniquities;
the punishment(D) that brought us peace(E) was on him,
    and by his wounds(F) we are healed.(G)
We all, like sheep, have gone astray,(H)
    each of us has turned to our own way;(I)
and the Lord has laid on him
    the iniquity(J) of us all.

Read full chapter