Add parallel Print Page Options

Má bẹ̀rù nítorí èmi wà pẹ̀lú rẹ;
    Èmi yóò mú àwọn ọmọ rẹ láti ìlà-oòrùn wá
    èmi ó sì kó ọ jọ láti ìwọ̀-oòrùn.

Read full chapter

Do not be afraid,(A) for I am with you;(B)
    I will bring your children(C) from the east
    and gather(D) you from the west.(E)

Read full chapter

(A)Olúwa sì sọ fún Paulu lóru ni ojúran pé, “Má bẹ̀rù, ṣá máa sọ, má sì ṣe pa ẹnu rẹ̀ mọ́: 10 Nítorí tí èmí wà pẹ̀lú rẹ, kò sì sí ẹni tí yóò dìde sí ọ láti pa ọ lára: nítorí mo ní ènìyàn púpọ̀ ni ìlú yìí.”

Read full chapter

One night the Lord spoke to Paul in a vision:(A) “Do not be afraid;(B) keep on speaking, do not be silent. 10 For I am with you,(C) and no one is going to attack and harm you, because I have many people in this city.”

Read full chapter