Add parallel Print Page Options

11 (A)Ó dára báyìí, pẹ̀lú ètè àjèjì àti ahọ́n àìmọ̀
    Ọlọ́run yóò bá àwọn ènìyàn yìí sọ̀rọ̀
12 (B)àwọn tí ó sọ fún wí pé,
    “Èyí ni ibi ìsinmi, jẹ́ kí àwọn aláàárẹ̀ sinmi”;
àti pé, “èyí ni ibi ìsinmi”
    ṣùgbọ́n wọn kò tẹ́tí sílẹ̀.

Read full chapter

11 Very well then, with foreign lips and strange tongues(A)
    God will speak to this people,(B)
12 to whom he said,
    “This is the resting place, let the weary rest”;(C)
and, “This is the place of repose”—
    but they would not listen.

Read full chapter