Add parallel Print Page Options

12 Efraimu ń jẹ afẹ́fẹ́;
    o ń lépa afẹ́fẹ́ ìwọ̀-oòrùn ní gbogbo ọjọ́.
    O sì ń gbèrú nínú irọ́
o dá májẹ̀mú pẹ̀lú Asiria
    o sì fi òróró olifi ránṣẹ́ sí Ejibiti.
Olúwa ní ẹjọ́ kan tí yóò bá Juda rò,
    yóò fì ìyà jẹ Jakọbu gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ̀
    yóò sì sán fún un gẹ́gẹ́ bí i ìṣe rẹ̀.
Láti inú oyún ni ó ti di arákùnrin rẹ̀ mú ni gìgísẹ̀,
    àti nípa ipá rẹ̀ ó ni agbára pẹ̀lú Ọlọ́run
Ó bá angẹli ja ìjàkadì, ó sì borí rẹ̀
    o sọkún, ó sì bẹ̀bẹ̀ fún ojúrere rẹ̀
Ó bá Olúwa ní Beteli
    Ó sì bá a sọ̀rọ̀ níbẹ̀,
àní Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun;
    Olúwa ni orúkọ ìrántí rẹ̀
Ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ padà sọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀;
    di ìfẹ́ àti ìdájọ́ òdodo mú
    kí ẹ sì dúró de Ọlọ́run yín nígbà gbogbo.

Oníṣòwò ń lo òṣùwọ̀n èké
    o fẹ́ràn láti rẹ́ ni jẹ.
(A)Efraimu gbéraga,
    “Èmi ní ìní fún ara mi, mo sì ti di ọlọ́rọ̀,
pẹ̀lú gbogbo ọrọ̀ mi yìí, wọn kò le ká àìṣedéédéé
    tàbí ẹ̀ṣẹ̀ kankan mọ́ mi lọ́wọ́.”

“Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ;
    ẹni tí ó mu ọ jáde wá láti ilẹ̀ Ejibiti;
èmi yóò tún mú yín gbé nínú àgọ́
    bí i ọjọ́ àjọ̀dún tí a yàn wọ̀n-ọn-nì
10 Mo sọ fún àwọn wòlíì,
    mo fi ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìran hàn wọ́n
    mo sì pa òwe láti ẹnu wòlíì wọn.”

11 Gileadi ha burú bí?
    Àwọn ènìyàn rẹ̀ jẹ́ asán.
Ǹjẹ́ wọ́n ń fi akọ màlúù rú ẹbọ ní Gilgali?
    Gbogbo pẹpẹ wọ́n sì dàbí ebè
    nínú aporo oko.
12 Jakọbu sálọ si orílẹ̀-èdè Aramu;
    Israẹli sìn kí o tó fẹ́ ìyàwó
    ó ṣe ìtọ́jú ẹran láti fi san owó ìyàwó.
13 Olúwa lo wòlíì kan láti mú Israẹli jáde wá láti Ejibiti,
    nípasẹ̀ wòlíì kan ó ṣe ìtọ́jú rẹ̀.
14 Ṣùgbọ́n Efraimu ti mú un bínú gidigidi;
    Olúwa rẹ̀ yóò sì fi ẹ̀bi ìtàjẹ̀ sílẹ̀ sí orí rẹ̀
    òun yóò sì san án padà fún un nítorí ìwà ẹ̀gàn an rẹ̀.

12 [a]Ephraim(A) feeds on the wind;(B)
    he pursues the east wind all day
    and multiplies lies and violence.(C)
He makes a treaty with Assyria(D)
    and sends olive oil to Egypt.(E)
The Lord has a charge(F) to bring against Judah;(G)
    he will punish(H) Jacob[b] according to his ways
    and repay him according to his deeds.(I)
In the womb he grasped his brother’s heel;(J)
    as a man he struggled(K) with God.
He struggled with the angel and overcame him;
    he wept and begged for his favor.
He found him at Bethel(L)
    and talked with him there—
the Lord God Almighty,
    the Lord is his name!(M)
But you must return(N) to your God;
    maintain love and justice,(O)
    and wait for your God always.(P)

The merchant uses dishonest scales(Q)
    and loves to defraud.
Ephraim boasts,(R)
    “I am very rich; I have become wealthy.(S)
With all my wealth they will not find in me
    any iniquity or sin.”

“I have been the Lord your God
    ever since you came out of Egypt;(T)
I will make you live in tents(U) again,
    as in the days of your appointed festivals.
10 I spoke to the prophets,
    gave them many visions
    and told parables(V) through them.”(W)

11 Is Gilead wicked?(X)
    Its people are worthless!
Do they sacrifice bulls in Gilgal?(Y)
    Their altars will be like piles of stones
    on a plowed field.(Z)
12 Jacob fled to the country of Aram[c];(AA)
    Israel served to get a wife,
    and to pay for her he tended sheep.(AB)
13 The Lord used a prophet to bring Israel up from Egypt,(AC)
    by a prophet he cared for him.(AD)
14 But Ephraim has aroused his bitter anger;
    his Lord will leave on him the guilt of his bloodshed(AE)
    and will repay him for his contempt.(AF)

Footnotes

  1. Hosea 12:1 In Hebrew texts 12:1-14 is numbered 12:2-15.
  2. Hosea 12:2 Jacob means he grasps the heel, a Hebrew idiom for he takes advantage of or he deceives.
  3. Hosea 12:12 That is, Northwest Mesopotamia