Add parallel Print Page Options

Ikú Jakọbu

29 Nígbà náà ni ó fún wọn ní àwọn ìlànà yìí, “Ọjọ́ ikú mi kù fẹ́ẹ́rẹ́. Kí ẹ sin mí sí ibojì pẹ̀lú àwọn baba mi ní inú àpáta ní ilẹ̀ Hiti ará Efroni. 30 (A)Ihò àpáta tí ó wà ní ilẹ̀ Makpela, nítòsí Mamre ní Kenaani, èyí tí Abrahamu rà gẹ́gẹ́ bí ilẹ̀ ìsìnkú lọ́wọ́ Efroni ará Hiti pẹ̀lú ilẹ̀ rẹ̀. 31 (B)Níbẹ̀ ni a sin Abrahamu àti aya rẹ̀ Sara sí, níbẹ̀ ni a sin Isaaki àti Rebeka aya rẹ̀ sí, níbẹ̀ sì ni mo sìnkú Lea sí. 32 Ilẹ̀ náà àti ihò àpáta tí ó wà nínú rẹ̀ ni a rà lọ́wọ́ ará Hiti.”

Read full chapter

The Death of Jacob

29 Then he gave them these instructions:(A) “I am about to be gathered to my people.(B) Bury me with my fathers(C) in the cave in the field of Ephron the Hittite,(D) 30 the cave in the field of Machpelah,(E) near Mamre(F) in Canaan, which Abraham bought along with the field(G) as a burial place(H) from Ephron the Hittite. 31 There Abraham(I) and his wife Sarah(J) were buried, there Isaac and his wife Rebekah(K) were buried, and there I buried Leah.(L) 32 The field and the cave in it were bought from the Hittites.[a](M)

Read full chapter

Footnotes

  1. Genesis 49:32 Or the descendants of Heth

Farao wí pé, “Gòkè lọ, kí o sì sin baba rẹ, bí ó tí mú ọ búra.”

Read full chapter

Pharaoh said, “Go up and bury your father, as he made you swear to do.”

Read full chapter