Add parallel Print Page Options

17 (A)Ọlọ́run sì wí fún Adamu pé, “Nítorí pé ìwọ fetí sí aya rẹ, ìwọ sì jẹ nínú èso igi tí mo pàṣẹ fún ọ pé ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ jẹ nínú rẹ̀,’

“Ègún ni fún ilẹ̀ nítorí rẹ;
    nínú ọ̀pọ̀ làálàá ni ìwọ yóò jẹ nínú rẹ̀,
    ní gbogbo ọjọ́ ayé rẹ.
18 Ilẹ̀ yóò sì hu ẹ̀gún àti èṣùṣú fún ọ,
    ewéko igbó ni ìwọ yóò sì máa jẹ.

Read full chapter