Add parallel Print Page Options

(A)Abramu gba Ọlọ́run gbọ́, a sì kà á sí òdodo fún un.

Read full chapter

Abram believed the Lord, and he credited it to him as righteousness.(A)

Read full chapter

Ìbùkún yìí ha jẹ́ ti àwọn akọlà nìkan, tàbí ti àwọn aláìkọlà pẹ̀lú? Nítorí tí a wí pé, Abrahamu gba Ọlọ́run gbọ́, a sì kà á sí òdodo fún un.

Read full chapter

Is this blessedness only for the circumcised, or also for the uncircumcised?(A) We have been saying that Abraham’s faith was credited to him as righteousness.(B)

Read full chapter

22 (A)Nítorí náà ni a sì ṣe kà á sí òdodo fún un.

Read full chapter

22 This is why “it was credited to him as righteousness.”(A)

Read full chapter

(A)Gẹ́gẹ́ bí Abrahamu “Ó gba Ọlọ́run gbọ́, a sì kà á sí òdodo fún un.”

Read full chapter

So also Abraham “believed God, and it was credited to him as righteousness.”[a](A)

Read full chapter

Footnotes

  1. Galatians 3:6 Gen. 15:6

23 (A)Ìwé Mímọ́ sì ṣẹ́ tí ó wí pé, “Abrahamu gba Ọlọ́run gbọ́, a sì kà á sí òdodo fún un,” a sì pè é ní ọ̀rẹ́ Ọlọ́run.

Read full chapter

23 And the scripture was fulfilled that says, “Abraham believed God, and it was credited to him as righteousness,”[a](A) and he was called God’s friend.(B)

Read full chapter

Footnotes

  1. James 2:23 Gen. 15:6