Add parallel Print Page Options

(A)mo sì ri ògo Ọlọ́run Israẹli ń bọ láti ìhà ìlà-oòrùn. Ohùn rẹ̀ dàbí híhó omi, ìtànṣán ògo rẹ̀ sì bo ilẹ̀.

Read full chapter

and I saw the glory of the God of Israel coming from the east. His voice was like the roar of rushing waters,(A) and the land was radiant with his glory.(B)

Read full chapter

15 (A)Ẹsẹ̀ rẹ̀ sì dàbí idẹ dáradára, bí ẹni pé a dà á nínú ìléru; ohùn rẹ̀ sì dàbí ìró omi púpọ̀.

Read full chapter

15 His feet were like bronze glowing in a furnace,(A) and his voice was like the sound of rushing waters.(B)

Read full chapter

Mo sì gbọ́ ohùn kan láti ọ̀run wá, bí ariwo omi púpọ̀, àti bí sísán àrá ńlá: mo sì gbọ́ àwọn aludùùrù tí wọn ń lu dùùrù.

Read full chapter

And I heard a sound from heaven like the roar of rushing waters(A) and like a loud peal of thunder.(B) The sound I heard was like that of harpists playing their harps.(C)

Read full chapter

Mo sì gbọ́ bí ẹni pé ohùn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, àti bí ìró omi púpọ̀, àti bí ìró àrá ńláńlá, ń wí pé:

“Haleluya!
Nítorí Olúwa Ọlọ́run wa, Olódùmarè ń jẹ ọba.

Read full chapter

Then I heard what sounded like a great multitude,(A) like the roar of rushing waters(B) and like loud peals of thunder, shouting:

“Hallelujah!(C)
    For our Lord God Almighty(D) reigns.(E)

Read full chapter