Add parallel Print Page Options

(A)Ṣùgbọ́n ìwọ, ọmọ ènìyàn, gbọ́ ohun tí mo ń sọ fún ọ. Má ṣe ṣọ̀tẹ̀ bí i ti ìdílé ọlọ́tẹ̀; la ẹnu rẹ kí o sì jẹ ohun tí mo fún ọ.”

Read full chapter

But you, son of man, listen to what I say to you. Do not rebel(A) like that rebellious people;(B) open your mouth and eat(C) what I give you.”

Read full chapter

Síwájú sí i, ó sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, jẹ ohun tí ó wà níwájú rẹ, jẹ ìwé kíká yìí; kí o sì lọ fi bá ilé Israẹli sọ̀rọ̀.” Mo sì ya ẹnu mi, ó sì mú mi jẹ ìwé kíká náà.

Ó tún sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, jẹ ìwé kíká tí mo fún ọ yìí, fi bọ́ inú àti ikùn rẹ.” Nígbà náà ni mo jẹ ẹ́, dídùn rẹ̀ dàbí oyin ní ẹnu mi.

Read full chapter

And he said to me, “Son of man, eat what is before you, eat this scroll; then go and speak to the people of Israel.” So I opened my mouth, and he gave me the scroll to eat.

Then he said to me, “Son of man, eat this scroll I am giving you and fill your stomach with it.” So I ate(A) it, and it tasted as sweet as honey(B) in my mouth.

Read full chapter