Add parallel Print Page Options

(A)Nígbà náà ní ó wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run baba rẹ, Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki àti Ọlọ́run Jakọbu.” Nítorí ìdí èyí, Mose sì pa ojú rẹ̀ mọ́, nítorí ó bẹ̀rù láti bojú wo Ọlọ́run.

Read full chapter

Then he said, “I am the God of your father,[a] the God of Abraham, the God of Isaac and the God of Jacob.”(A) At this, Moses hid(B) his face, because he was afraid to look at God.(C)

Read full chapter

Footnotes

  1. Exodus 3:6 Masoretic Text; Samaritan Pentateuch (see Acts 7:32) fathers

Ìpọ́njú àti ògo ìránṣẹ́ náà

13 Kíyèsi i, ìránṣẹ́ mi yóò hùwà ọlọ́gbọ́n;
    òun ni a ó gbé sókè tí a ó sì gbéga
    a ó sì gbé e lékè gidigidi.

Read full chapter

The Suffering and Glory of the Servant

13 See, my servant(A) will act wisely[a];
    he will be raised and lifted up and highly exalted.(B)

Read full chapter

Footnotes

  1. Isaiah 52:13 Or will prosper