Add parallel Print Page Options

16 “Ṣe àjọ ìkórè pẹ̀lú èso àkọ́so ọ̀gbìn oko rẹ.

“Ṣe àjọ àkójọ oko rẹ ní òpin ọdún, nígbà tí ìwọ bá kó ìre oko rẹ jọ tan.

Read full chapter

16 “Celebrate the Festival of Harvest(A) with the firstfruits(B) of the crops you sow in your field.

“Celebrate the Festival of Ingathering(C) at the end of the year, when you gather in your crops from the field.(D)

Read full chapter

22 (A)“Ṣe àjọ ọ̀sẹ̀ pẹ̀lú àkọ́so èso alikama àti àjọ ìkórè ní òpin ọdún.

Read full chapter

22 “Celebrate the Festival of Weeks with the firstfruits(A) of the wheat harvest, and the Festival of Ingathering(B) at the turn of the year.[a]

Read full chapter

Footnotes

  1. Exodus 34:22 That is, in the autumn

Ọdún àwọn ọ̀sẹ̀ Pentikosti

15 “ ‘Ẹ ka ọ̀sẹ̀ méje gbangba, láti ọjọ́ kejì ọjọ́ ìsinmi, àní ọjọ́ tí ẹ mú ìdì ọkà fífì wá. 16 Ẹ ka àádọ́ta (50) ọjọ́ títí dé ọjọ́ kejì ọ̀sẹ̀ méjèèje, kí ẹ sì mú ọrẹ ọkà tuntun wá fún Olúwa. 17 Láti ibikíbi tí ẹ bá ń gbé, ẹ mú ìṣù àkàrà méjì tí a fi òṣùwọ̀n ìdá méjì nínú mẹ́wàá tí efa (Èyí jẹ́ lítà mẹ́rin ààbọ̀) ti ìyẹ̀fun, tí a fi ìwúkàrà ṣe, gẹ́gẹ́ bí ọrẹ fífì àkọ́so sí Olúwa. 18 Ẹ fi akọ ọ̀dọ́-àgùntàn méje ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan tí kò ní àbùkù, ọmọ màlúù kan àti àgbò méjì kún àkàrà yìí: wọn yóò jẹ́ ẹbọ sísun sí Olúwa, pẹ̀lú ẹbọ ohun jíjẹ àti ẹbọ ohun mímu wọn, àní ẹbọ tí a fi iná ṣe, olóòórùn dídùn ni sí Olúwa. 19 Lẹ́yìn náà kí ẹ fi akọ ewúrẹ́ kan rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, àti ọ̀dọ́-àgùntàn méjì ọlọ́dún kọ̀ọ̀kan fún ọrẹ àlàáfíà. 20 Kí àlùfáà fi ọ̀dọ́-àgùntàn méjèèjì náà níwájú Olúwa bí i ọrẹ fífì pẹ̀lú oúnjẹ àkọ́so wọn jẹ́ ọrẹ mímọ́ sí Olúwa fún àlùfáà. 21 Ní ọjọ́ yìí náà ni kí ẹ kéde ìpàdé àjọ mímọ́: ẹ kò sì gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ kankan. Èyí yóò jẹ́ ìlànà ayérayé fún àwọn ìran tí ń bọ̀ níbi yówù tí ẹ ń gbé.

Read full chapter

The Festival of Weeks(A)

15 “‘From the day after the Sabbath, the day you brought the sheaf of the wave offering, count off seven full weeks. 16 Count off fifty days up to the day after the seventh Sabbath,(B) and then present an offering of new grain to the Lord. 17 From wherever you live, bring two loaves made of two-tenths of an ephah(C) of the finest flour, baked with yeast, as a wave offering of firstfruits(D) to the Lord. 18 Present with this bread seven male lambs, each a year old and without defect, one young bull and two rams. They will be a burnt offering to the Lord, together with their grain offerings and drink offerings(E)—a food offering, an aroma pleasing to the Lord. 19 Then sacrifice one male goat for a sin offering[a] and two lambs, each a year old, for a fellowship offering. 20 The priest is to wave the two lambs before the Lord as a wave offering,(F) together with the bread of the firstfruits. They are a sacred offering to the Lord for the priest. 21 On that same day you are to proclaim a sacred assembly(G) and do no regular work.(H) This is to be a lasting ordinance for the generations to come, wherever you live.

Read full chapter

Footnotes

  1. Leviticus 23:19 Or purification offering

Ayẹyẹ àwọn ọ̀sẹ̀

Ka ọ̀sẹ̀ méje láti ìgbà tí ẹ bá ti bẹ̀rẹ̀ sí fi dòjé ṣe ìkórè ọkà. 10 Nígbà náà ni kí ẹ ṣe àjọ ọ̀sẹ̀ sí Olúwa Ọlọ́run yín, nípa pípèsè ọrẹ àtinúwá, gẹ́gẹ́ bí ìbùkún tí Olúwa Ọlọ́run yín fún un yín. 11 Kí ẹ sì máa yọ̀ níwájú Olúwa Ọlọ́run yín ní ibi tí yóò yàn ní ibùgbé fún orúkọ rẹ̀: ẹ̀yin, àwọn ọmọ yín ọkùnrin àti àwọn ọmọ yín obìnrin, àwọn ẹrú yín ọkùnrin àti àwọn ẹrú yín obìnrin, àwọn Lefi tí ó wà ní ìlú yín, àti àwọn àjèjì, àwọn aláìní baba, àti àwọn opó tí ń gbé àárín yín. 12 Ẹ rántí pé, ẹ ti jẹ́ ẹrú ní Ejibiti rí, nítorí náà ẹ tẹ̀lé àwọn ìlànà wọ̀nyí dáradára.

Read full chapter

The Festival of Weeks(A)

Count off seven weeks(B) from the time you begin to put the sickle to the standing grain.(C) 10 Then celebrate the Festival of Weeks to the Lord your God by giving a freewill offering in proportion to the blessings the Lord your God has given you. 11 And rejoice(D) before the Lord your God at the place he will choose as a dwelling for his Name(E)—you, your sons and daughters, your male and female servants, the Levites(F) in your towns, and the foreigners,(G) the fatherless and the widows living among you.(H) 12 Remember that you were slaves in Egypt,(I) and follow carefully these decrees.

Read full chapter