Add parallel Print Page Options

19 (A)“Ẹnikẹ́ni ti ó bá bá ẹranko lòpọ̀ ní a ó pa.

Read full chapter

19 “Anyone who has sexual relations with an animal(A) is to be put to death.

Read full chapter

15 (A)“ ‘Bí ọkùnrin kan bá bá ẹranko lòpọ̀, ẹ gbọdọ̀ pa ọkùnrin náà àti ẹranko náà.

Read full chapter

15 “‘If a man has sexual relations with an animal,(A) he is to be put to death,(B) and you must kill the animal.

Read full chapter

16 “ ‘Bí obìnrin kan bá súnmọ́ ẹranko tí ó sì bá a lòpọ̀ obìnrin náà àti ẹranko náà ni kí ẹ pa: ẹ̀jẹ̀ wọn yóò sì wà lórí ara wọn.

Read full chapter

16 “‘If a woman approaches an animal to have sexual relations with it, kill both the woman and the animal. They are to be put to death; their blood will be on their own heads.

Read full chapter

21 (A)“Ègún ni fún ọkùnrin náà tí ó ní ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ẹranko.”

Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn wọ̀nyí yóò wí pé, “Àmín!”

Read full chapter

21 “Cursed is anyone who has sexual relations with any animal.”(A)

Then all the people shall say, “Amen!”

Read full chapter