Add parallel Print Page Options

46 (A)“Nínú ilé ni ẹ ti gbọdọ̀ jẹ ẹ́; ẹ kò gbọdọ̀ mú èyíkéyìí nínú ẹran náà jáde kúrò nínú ilé. Ẹ má ṣe ṣẹ́ ọ̀kankan nínú egungun rẹ̀.

Read full chapter

46 “It must be eaten inside the house; take none of the meat outside the house. Do not break any of the bones.(A)

Read full chapter

12 (A)Wọn kò gbọdọ̀ ṣẹ́ ọ̀kankan kù di àárọ̀, wọn kò sì gbọdọ̀ ṣẹ́ eegun rẹ̀. Wọ́n gbọdọ̀ tẹ̀lé gbogbo ìlànà fún ṣíṣe àjọ Ìrékọjá.

Read full chapter

12 They must not leave any of it till morning(A) or break any of its bones.(B) When they celebrate the Passover, they must follow all the regulations.(C)

Read full chapter

20 Ó pa gbogbo egungun wọn mọ́;
    kò sí ọ̀kan tí ó dá nínú wọn.

Read full chapter

20 he protects all his bones,
    not one of them will be broken.(A)

Read full chapter