Add parallel Print Page Options

15 San owó iṣẹ́ rẹ̀ ní ọjọ́ kan náà kí ó tó di àṣálẹ́, nítorí ó jẹ́ tálákà, ó sì gbẹ́kẹ̀lé e bí kò ṣe bẹ́ẹ̀ ó lè ké pe Olúwa sí ọ, o sì máa gba ìdálẹ́bi ẹ̀ṣẹ̀.

Read full chapter

15 Pay them their wages each day before sunset, because they are poor(A) and are counting on it.(B) Otherwise they may cry to the Lord against you, and you will be guilty of sin.(C)

Read full chapter

Kíyèsi i, ọ̀yà àwọn alágbàṣe tí wọ́n ti ṣe ìkórè oko yín, èyí tí ẹ kò san, ń ké rara; àti igbe àwọn tí ó ṣe ìkórè sì ti wọ inú etí Olúwa àwọn ọmọ-ogun.

Read full chapter

Look! The wages you failed to pay the workers(A) who mowed your fields are crying out against you. The cries(B) of the harvesters have reached the ears of the Lord Almighty.(C)

Read full chapter