Add parallel Print Page Options

Sí sin àwọn ọlọ́run mìíràn

13 Bí wòlíì tàbí alásọtẹ́lẹ̀ nípa àlá lílá bá farahàn láàrín yín, tí ó sì ń kéde iṣẹ́ ààmì tàbí iṣẹ́ ìyanu, bí iṣẹ́ ààmì tàbí iṣẹ́ ìyanu tí ó sọ̀rọ̀ rẹ̀ bá ṣẹ tí òun sì wí pé, “ẹ wá ẹ jẹ́ kí a tẹ̀lé ọlọ́run mìíràn” (àwọn ọlọ́run tí ẹ kò mọ̀ rí) “kí ẹ sì jẹ́ kí a máa sìn wọ́n,” ẹ má fetí sí ọ̀rọ̀ wòlíì tàbí àlá náà, Olúwa Ọlọ́run yín ń dán an yín wò ni, láti mọ̀ bóyá ẹ fẹ́ràn rẹ̀ pẹ̀lú gbogbo àyà yín àti gbogbo ọkàn an yín. Olúwa Ọlọ́run yín ni kí ẹ tẹ̀lé, Òun ni kí ẹ bu ọlá fún, ẹ pa òfin rẹ̀ mọ́ kí ẹ sì gbọ́ tirẹ̀: ẹ sìn ín, kí ẹ sì dìímú ṣinṣin. Wòlíì náà tàbí alálàá náà ni kí ẹ pa, nítorí pé wàásù ìṣọ̀tẹ̀ sí Olúwa Ọlọ́run yín, tí ó mú yín jáde láti Ejibiti wá, tí ó sì rà yín padà lóko ẹrú. Ó ti gbìyànjú láti fà yín kúrò lójú ọ̀nà tí Olúwa Ọlọ́run yín ti pàṣẹ fún un yín láti máa rìn. Ẹ gbọdọ̀ yọ ibi náà kúrò láàrín yín.

Read full chapter

Worshiping Other Gods

13 [a]If a prophet,(A) or one who foretells by dreams,(B) appears among you and announces to you a sign or wonder, and if the sign(C) or wonder spoken of takes place, and the prophet says, “Let us follow other gods”(D) (gods you have not known) “and let us worship them,” you must not listen to the words of that prophet(E) or dreamer.(F) The Lord your God is testing(G) you to find out whether you love(H) him with all your heart and with all your soul. It is the Lord your God you must follow,(I) and him you must revere.(J) Keep his commands and obey him; serve him and hold fast(K) to him. That prophet or dreamer must be put to death(L) for inciting rebellion against the Lord your God, who brought you out of Egypt and redeemed you from the land of slavery. That prophet or dreamer tried to turn(M) you from the way the Lord your God commanded you to follow. You must purge the evil(N) from among you.

Read full chapter

Footnotes

  1. Deuteronomy 13:1 In Hebrew texts 13:1-18 is numbered 13:2-19.