Add parallel Print Page Options

16 Mo gbọ́ ohùn ènìyàn ní ẹ̀gbẹ́ Ulai, tí ó ń ké pé “Gebrieli, sọ ìtumọ̀ ìran náà fún ọkùnrin yìí.”

Read full chapter

16 And I heard a man’s voice from the Ulai(A) calling, “Gabriel,(B) tell this man the meaning of the vision.”(C)

Read full chapter

21 Bí mo ṣe ń gba àdúrà náà lọ́wọ́, Gebrieli ọkùnrin tí mo rí nínú ìran ìṣáájú, yára kánkán wá sí ọ̀dọ̀ mi ní àkókò ẹbọ àṣálẹ́.

Read full chapter

21 while I was still in prayer, Gabriel,(A) the man I had seen in the earlier vision, came to me in swift flight about the time of the evening sacrifice.(B)

Read full chapter

Òwe àgùntàn tó sọnù

10 (A)“Ẹ rí i pé ẹ kò fi ojú tẹ́ńbẹ́lú ọ̀kan nínú àwọn kéékèèkéé wọ̀nyí. Lóòótọ́ ni mo wí fún yin pé, nígbà gbogbo ni ọ̀run ni àwọn angẹli ń wo ojú Baba mi tí ń bẹ ní ọ̀run.

Read full chapter

The Parable of the Wandering Sheep(A)

10 “See that you do not despise one of these little ones. For I tell you that their angels(B) in heaven always see the face of my Father in heaven.

Read full chapter