Add parallel Print Page Options

Ọba tí ó gbé ara rẹ̀ ga

36 “Ọba yóò ṣe bí ó ti wù ú yóò sì gbé ara rẹ̀ ga, ju gbogbo òrìṣà lọ, yóò máa sọ àwọn ọ̀rọ̀ tí kò-ṣe-é-gbọ́-létí sí Ọlọ́run àwọn Ọlọ́run, yóò sì máa yege títí àkókò ìbínú yóò fi parí, nítorí ohun tí a ti pinnu yóò ṣẹlẹ̀.

Read full chapter

The King Who Exalts Himself

36 “The king will do as he pleases. He will exalt and magnify himself(A) above every god and will say unheard-of things(B) against the God of gods.(C) He will be successful until the time of wrath(D) is completed, for what has been determined must take place.(E)

Read full chapter

(A)Òun yóò lòdì sí, yóò sì gbé ara rẹ̀ ga sí gbogbo ohun tí a ń pè ní Ọlọ́run tàbí tí a ń sìn, dé ibi pé yóò gbé ara rẹ̀ jókòó nínú tẹmpili Ọlọ́run, tí yóò sì pe ara rẹ̀ ní Ọlọ́run.

Read full chapter

He will oppose and will exalt himself over everything that is called God(A) or is worshiped, so that he sets himself up in God’s temple, proclaiming himself to be God.(B)

Read full chapter

(A)A sì fún un ni ẹnu láti má sọ ohun ńlá àti ọ̀rọ̀-òdì, a sì fi agbára fún un láti ṣe bẹ́ẹ̀ ni oṣù méjìlélógójì.

Read full chapter

The beast was given a mouth to utter proud words and blasphemies(A) and to exercise its authority for forty-two months.(B)

Read full chapter