Add parallel Print Page Options

(A)Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, ẹ pe orúkọ rẹ̀,
    ẹ fi iṣẹ́ rẹ̀ hàn nínú àwọn ènìyàn fún ohun tí ó ṣe
Ẹ kọrin sí i, ẹ kọrin ìyìn, sí i,
    Ẹ sọ ti gbogbo iṣẹ́ ìyanu rẹ̀
10 Ìyìn nínú orúkọ rẹ̀ mímọ́;
    jẹ kí ọkàn àwọn tí ó yin Olúwa kí ó yọ̀.
11 Ẹ wá Olúwa àti agbára rẹ̀;
    E wá ojú rẹ̀ nígbà gbogbo.

12 Rántí àwọn ìyanu tí Ó ti ṣe,
    iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ àti ìdájọ́ tí Ó ti sọ.
13 A! ẹ̀yin ìran ọmọ Israẹli ìránṣẹ́ rẹ̀,
    àwọn ọmọ Jakọbu, ẹ̀yin tí ó ti yàn.
14 Òun ni Olúwa Ọlọ́run wa;
    ìdájọ́ rẹ̀ wà ní gbogbo ayé.

15 Ó rántí májẹ̀mú rẹ̀ láéláé,
    ọ̀rọ̀ tí ó pàṣẹ, fún ẹgbẹgbẹ̀rún ìran,
16 májẹ̀mú tí ó dá pẹ̀lú Abrahamu,
    ìbúra tí ó ṣe pẹ̀lú fún Isaaki.
17 Ó ṣe ìdánilójú u rẹ̀ fún Jakọbu,
    gẹ́gẹ́ bí àṣẹ sí Israẹli, gẹ́gẹ́ bi májẹ̀mú ayérayé:
18 “Sí ọ, ni Èmi yóò fún ní ilẹ̀ Kenaani.
    Gẹ́gẹ́ bí ààyè tí ìwọ yóò jogún.”

19 Nígbà tí wọn kéré ní iye,
    wọ́n kéré gidigidi, wọ́n sì jẹ́ àlejò níbẹ̀,
20 wọ́n rìn kiri láti orílẹ̀-èdè sí orílẹ̀-èdè
    láti ìjọba kan sí èkejì.
21 Kò gba ọkùnrin kankan láyè láti pọ́n wọn lójú;
    nítorí tiwọn, ó bá àwọn ọba wí.
22 “Má ṣe fọwọ́ kan àwọn ẹni ààmì òróró mi;
    Má ṣe pa àwọn wòlíì mi lára.”

Read full chapter

Give praise(A) to the Lord, proclaim his name;
    make known among the nations(B) what he has done.
Sing to him, sing praise(C) to him;
    tell of all his wonderful acts.
10 Glory in his holy name;(D)
    let the hearts of those who seek the Lord rejoice.
11 Look to the Lord and his strength;
    seek(E) his face always.

12 Remember(F) the wonders(G) he has done,
    his miracles,(H) and the judgments he pronounced,
13 you his servants, the descendants of Israel,
    his chosen ones, the children of Jacob.
14 He is the Lord our God;
    his judgments(I) are in all the earth.

15 He remembers[a](J) his covenant forever,
    the promise he made, for a thousand generations,
16 the covenant(K) he made with Abraham,
    the oath he swore to Isaac.
17 He confirmed it to Jacob(L) as a decree,
    to Israel as an everlasting covenant:
18 “To you I will give the land of Canaan(M)
    as the portion you will inherit.”

19 When they were but few in number,(N)
    few indeed, and strangers in it,
20 they[b] wandered(O) from nation to nation,
    from one kingdom to another.
21 He allowed no one to oppress them;
    for their sake he rebuked kings:(P)
22 “Do not touch my anointed ones;
    do my prophets(Q) no harm.”

Read full chapter

Footnotes

  1. 1 Chronicles 16:15 Some Septuagint manuscripts (see also Psalm 105:8); Hebrew Remember
  2. 1 Chronicles 16:20 One Hebrew manuscript, Septuagint and Vulgate (see also Psalm 105:12); most Hebrew manuscripts inherit, / 19 though you are but few in number, / few indeed, and strangers in it.” / 20 They