Add parallel Print Page Options

Lórí ìyapa nínú ìjọ

(A)Ará, èmí kò sí le bá yín sọ̀rọ̀ bí àwọn tí í ṣe ti Ẹ̀mí, bí kò ṣe bí àwọn ti í ṣe ti ara, àní bí àwọn ọmọ ọwọ́ nínú Kristi.

Read full chapter

The Church and Its Leaders

Brothers and sisters, I could not address you as people who live by the Spirit(A) but as people who are still worldly(B)—mere infants(C) in Christ.

Read full chapter

37 Bí ẹnikẹ́ni bá ró ará rẹ̀ pé òun jẹ́ wòlíì, tàbí òun jẹ́ ẹni tí ó ní ẹ̀bùn ẹ̀mí, jẹ́ kí nǹkan wọ̀nyí ti mo kọ sí yin yé e dájú pé òfin Olúwa ni wọ́n.

Read full chapter

37 If anyone thinks they are a prophet(A) or otherwise gifted by the Spirit,(B) let them acknowledge that what I am writing to you is the Lord’s command.(C)

Read full chapter

Ṣíṣe dáradára sí gbogbo ènìyàn

Ará, bí a tilẹ̀ mú ènìyàn nínú ẹ̀ṣẹ̀ kan, kí ẹ̀yin tí í ṣe ti Ẹ̀mí mú irú ẹni bẹ́ẹ̀ bọ̀ sípò nínú ẹ̀mí ìwà tútù; kí ìwọ tìkára rẹ̀ máa kíyèsára, kí a má ba à dán ìwọ náà wò pẹ̀lú.

Read full chapter

Doing Good to All

Brothers and sisters, if someone is caught in a sin, you who live by the Spirit(A) should restore(B) that person gently. But watch yourselves, or you also may be tempted.

Read full chapter