Add parallel Print Page Options

(A)Nígba tí èmí tọ̀ yín wá, ẹ̀yin ará, kì í ṣe nípa ọ̀rọ̀ gíga àti ọgbọ́n gíga ni mo fi bá yín sọ̀rọ̀, nígbà tí èmi ń sọ̀rọ̀ ohun ìjìnlẹ̀ Ọlọ́run fún un yín. (B)Èmi ti pinnu láti má mọ ohunkóhun nígbà ti mo wà láàrín yín bí kò ṣe Jesu Kristi, ẹni tí a kàn mọ́ àgbélébùú. (C)Èmi sì tọ̀ yín wá ni àìlera, àti ní ẹ̀rù, àti ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìwárìrì. (D)Ìwàásù mi àti ẹ̀kọ́ mi, kì í ṣe nípa ọgbọ́n ènìyàn àti ọ̀rọ̀ tí a fi ń yí ènìyàn lọ́kàn padà, bí kò ṣe nípa ìfihàn agbára Ẹ̀mí. (E)Kí ìgbàgbọ́ yín kí ó má ṣe dúró lórí ọgbọ́n ènìyàn, ṣùgbọ́n kí ó dúró lórí agbára Ọlọ́run.

Ọgbọ́n láti ọ̀dọ̀ ẹ̀mí wá

(F)Ṣùgbọ́n àwa ń sọ̀rọ̀ ọgbọ́n láàrín àwọn tí a pè; ṣùgbọ́n kì í ṣe ọgbọ́n ti ayé yìí tàbí ti àwọn olórí ayé yìí, èyí tí yóò di asán (G)Bẹ́ẹ̀ kọ́, àwa ń sọ̀rọ̀ ọgbọ́n ti Ọlọ́run tó fi ara sin, ọgbọ́n tí ó ti fi ara pamọ́, èyí tí Ọlọ́run ti lànà sílẹ̀ ṣáájú ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé fún ògo wa. (H)Èyí ti ẹnikẹ́ni nínú àwọn aláṣẹ ayé yìí kò mọ̀. Ìbá ṣe pé wọ́n mọ̀ ọ́n, wọn kì bá tún kan Olúwa ògo mọ́ àgbélébùú. (I)Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé:

“Ojú kò tí ì rí,
    etí kò tí í gbọ́,
kò sì ọkàn ènìyàn tí ó tí í mọ̀
ohun tí Ọlọ́run tí pèsè sílẹ̀ fún àwọn tí o fẹ́ Ẹ.”

10 (J)Ṣùgbọ́n Ọlọ́run ti fi í hàn fún wa nípasẹ̀ Ẹ̀mí rẹ̀.

Ẹ̀mí á máa wádìí ohun gbogbo, kódà àwọn àṣírí Ọlọ́run tó jinlẹ̀ jùlọ. 11 Ta ni nínú ènìyàn tí ó mọ èrò ọkàn ènìyàn kan, bí kò ṣe ẹ̀mí ènìyàn tí ó wà nínú rẹ̀? Bákan náà, kò sí ẹni ti ó mọ àwọn èrò Ọlọ́run, bí kò ṣe Ẹ̀mí Ọlọ́run fúnrarẹ̀. 12 (K)Àwa kò gbà ẹ̀mí ti ayé yìí, bí kò ṣe Ẹ̀mí ẹni tí ó ti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wa, kí a lè ní òye ohun tí Ọlọ́run fi fún wa lọ́fẹ̀ẹ́. 13 (L)Èyí ni àwa ń wí, kì í ṣe èyí tí a ń kọ nípa ọ̀rọ̀ ọgbọ́n ènìyàn, ṣùgbọ́n èyí tí Ẹ̀mí Mímọ́ fi ń kọ ènìyàn, èyí tí a ń fi ohun Ẹ̀mí wé ohun Ẹ̀mí. 14 (M)Ṣùgbọ́n ènìyàn nípa ti ara kò gba ohun ti Ẹ̀mí Ọlọ́run wọ̀n-ọ́n-nì, nítorí pé wèrè ni wọ́n jásí fún un, òun kò sì le mọ̀ wọ́n, nítorí nípa tí Ẹ̀mí ní a fi ń wádìí wọn. 15 (N)Ṣùgbọ́n ẹni tí ó wà nípa ti ẹ̀mí ń wádìí ohun gbogbo, ṣùgbọ́n kò sí ẹnikẹ́ni tí í wádìí rẹ̀.

16 (O)“Nítorí ta ni ó mọ ọkàn Olúwa,
    ti yóò fi máa kọ́ Ọ?”

Ṣùgbọ́n àwa ní inú Kristi.

And so it was with me, brothers and sisters. When I came to you, I did not come with eloquence or human wisdom(A) as I proclaimed to you the testimony about God.[a] For I resolved to know nothing while I was with you except Jesus Christ and him crucified.(B) I came to you(C) in weakness(D) with great fear and trembling.(E) My message and my preaching were not with wise and persuasive words,(F) but with a demonstration of the Spirit’s power,(G) so that your faith might not rest on human wisdom, but on God’s power.(H)

God’s Wisdom Revealed by the Spirit

We do, however, speak a message of wisdom among the mature,(I) but not the wisdom of this age(J) or of the rulers of this age, who are coming to nothing.(K) No, we declare God’s wisdom, a mystery(L) that has been hidden(M) and that God destined for our glory before time began. None of the rulers of this age(N) understood it, for if they had, they would not have crucified the Lord of glory.(O) However, as it is written:

“What no eye has seen,
    what no ear has heard,
and what no human mind has conceived”[b]
    the things God has prepared for those who love him—(P)

10 these are the things God has revealed(Q) to us by his Spirit.(R)

The Spirit searches all things, even the deep things of God. 11 For who knows a person’s thoughts(S) except their own spirit(T) within them? In the same way no one knows the thoughts of God except the Spirit of God. 12 What we have received is not the spirit(U) of the world,(V) but the Spirit who is from God, so that we may understand what God has freely given us. 13 This is what we speak, not in words taught us by human wisdom(W) but in words taught by the Spirit, explaining spiritual realities with Spirit-taught words.[c] 14 The person without the Spirit does not accept the things that come from the Spirit of God(X) but considers them foolishness,(Y) and cannot understand them because they are discerned only through the Spirit. 15 The person with the Spirit(Z) makes judgments about all things, but such a person is not subject to merely human judgments, 16 for,

“Who has known the mind of the Lord
    so as to instruct him?”[d](AA)

But we have the mind of Christ.(AB)

Footnotes

  1. 1 Corinthians 2:1 Some manuscripts proclaimed to you God’s mystery
  2. 1 Corinthians 2:9 Isaiah 64:4
  3. 1 Corinthians 2:13 Or Spirit, interpreting spiritual truths to those who are spiritual
  4. 1 Corinthians 2:16 Isaiah 40:13

And I, brethren, when I came to you, came not with excellency of speech or of wisdom, declaring unto you the testimony of God.

For I determined not to know any thing among you, save Jesus Christ, and him crucified.

And I was with you in weakness, and in fear, and in much trembling.

And my speech and my preaching was not with enticing words of man's wisdom, but in demonstration of the Spirit and of power:

That your faith should not stand in the wisdom of men, but in the power of God.

Howbeit we speak wisdom among them that are perfect: yet not the wisdom of this world, nor of the princes of this world, that come to nought:

But we speak the wisdom of God in a mystery, even the hidden wisdom, which God ordained before the world unto our glory:

Which none of the princes of this world knew: for had they known it, they would not have crucified the Lord of glory.

But as it is written, Eye hath not seen, nor ear heard, neither have entered into the heart of man, the things which God hath prepared for them that love him.

10 But God hath revealed them unto us by his Spirit: for the Spirit searcheth all things, yea, the deep things of God.

11 For what man knoweth the things of a man, save the spirit of man which is in him? even so the things of God knoweth no man, but the Spirit of God.

12 Now we have received, not the spirit of the world, but the spirit which is of God; that we might know the things that are freely given to us of God.

13 Which things also we speak, not in the words which man's wisdom teacheth, but which the Holy Ghost teacheth; comparing spiritual things with spiritual.

14 But the natural man receiveth not the things of the Spirit of God: for they are foolishness unto him: neither can he know them, because they are spiritually discerned.

15 But he that is spiritual judgeth all things, yet he himself is judged of no man.

16 For who hath known the mind of the Lord, that he may instruct him? but we have the mind of Christ.