Add parallel Print Page Options

(A)Nígbà tí àwọn ẹ̀dá alààyè náà bá sì fi ògo àti ọlá, àti ọpẹ́ fún ẹni tí o jókòó lórí ìtẹ́, tí o ń bẹ láààyè láé àti láéláé.

Read full chapter

Whenever the living creatures give glory, honor and thanks to him who sits on the throne(A) and who lives for ever and ever,(B)

Read full chapter

(A)Angẹli náà tí mo rí tí ó dúró lórí Òkun àti lórí ilẹ̀, sì gbé ọwọ́ rẹ̀ sí òkè ọ̀run:

Read full chapter

Then the angel I had seen standing on the sea and on the land(A) raised his right hand to heaven.(B)

Read full chapter

14 (A)A sì fi apá ìyẹ́ méjì tí idì ńlá náà fún obìnrin náà, pé kí ó fò lọ sí aginjù, sí ipò rẹ̀, níbi tí a ó gbe bọ ọ fún àkókò kan àti fún àwọn àkókò, àti fún ìdajì àkókò kúrò lọ́dọ̀ ejò náà.

Read full chapter

14 The woman was given the two wings of a great eagle,(A) so that she might fly to the place prepared for her in the wilderness, where she would be taken care of for a time, times and half a time,(B) out of the serpent’s reach.

Read full chapter